Add parallel Print Page Options

29 Ẹ gbé àjàgà mi wọ̀. Ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ lọ́dọ̀ mi nítorí onínútútù àti onírẹ̀lẹ̀ ọkàn ni èmi, ẹ̀yin yóò sì ri ìsinmi fún ọkàn yín.

Read full chapter

29 Take my yoke upon you and learn from me,(A) for I am gentle and humble in heart, and you will find rest for your souls.(B)

Read full chapter

28 Gẹ́gẹ́ bí Ọmọ Ènìyàn kò ṣe wá sí ayé, kí ẹ lè ṣe ìránṣẹ́ fún un, ṣùgbọ́n láti ṣe ìránṣẹ́ fún yín, àti láti fi ẹ̀mí rẹ ṣe ìràpadà ọ̀pọ̀ ènìyàn.”

Read full chapter

28 just as the Son of Man(A) did not come to be served, but to serve,(B) and to give his life as a ransom(C) for many.”

Read full chapter

Ọ̀rọ̀ di ẹran-ara

(A)Ní àtètèkọ́ṣe ni Ọ̀rọ̀ wà, Ọ̀rọ̀ sì wà pẹ̀lú Ọlọ́run, Ọlọ́run sì ni Ọ̀rọ̀ náà.

Read full chapter

The Word Became Flesh

In the beginning was the Word,(A) and the Word was with God,(B) and the Word was God.(C)

Read full chapter

(A)Nítorí ẹ̀yin mọ oore-ọ̀fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi, pé bí òun ti jẹ́ ọlọ́rọ̀ rí ṣùgbọ́n nítorí yín ó di tálákà kí a lè sọ yín di ọlọ́rọ̀ nípa àìní rẹ̀.

Read full chapter

For you know the grace(A) of our Lord Jesus Christ,(B) that though he was rich, yet for your sake he became poor,(C) so that you through his poverty might become rich.(D)

Read full chapter

Bí òun tilẹ̀ ń ṣe Ọmọ Ọlọ́run, síbẹ̀ ó kọ́ ìgbọ́ran nípa ohun tí ó jìyà rẹ̀;

Read full chapter

Son(A) though he was, he learned obedience from what he suffered(B)

Read full chapter