Add parallel Print Page Options

23 A ó rẹ òṣùpá sílẹ̀, ojú yóò sì ti oòrùn;
    nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò jẹ ọba
ní orí òkè Sioni àti ní Jerusalẹmu,
    àti níwájú àwọn àgbàgbà rẹ ní ògo.

Read full chapter

Ògo Sioni

60 “Dìde, tànmọ́lẹ̀, nítorí ìmọ́lẹ̀ rẹ ti dé,
    ògo Olúwa sì ràdàbò ọ́.

Read full chapter

19 Òòrùn kì yóò sì jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ní ọ̀sán mọ́,
    tàbí kí ìtànṣán òṣùpá tún ràn sí ọ mọ́,
nítorí Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ayérayé,
    àti Ọlọ́run rẹ yóò jẹ́ ògo rẹ.

Read full chapter