Add parallel Print Page Options

14 “Ṣùgbọ́n ó tẹ̀síwájú nínú ṣíṣe panṣágà. O ri àwòrán àwọn ọkùnrin lára ògiri, àwòrán àwọn ara Kaldea àwòrán pupa, 15 pẹ̀lú ìgbànú ni ìdí wọn àti àwọn ìgbàrí ni orí wọn; gbogbo wọn dàbí olórí kẹ̀kẹ́ ogun Babeli ọmọ ìlú Kaldea. 16 Ní kété tí ó rí wọn, ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí wọn, ó sì rán oníṣẹ́ sí wọn ni Kaldea. 17 Àwọn ará Babeli wá sọ́dọ̀ rẹ̀, lórí ibùsùn ìfẹ́, nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn, wọ́n bà á jẹ́. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n bà á jẹ́ tán, ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn ní ìtìjú.

Read full chapter

14 “But she carried her prostitution still further. She saw men portrayed on a wall,(A) figures of Chaldeans[a] portrayed in red,(B) 15 with belts(C) around their waists and flowing turbans on their heads; all of them looked like Babylonian chariot officers, natives of Chaldea.[b] 16 As soon as she saw them, she lusted after them and sent messengers(D) to them in Chaldea.(E) 17 Then the Babylonians(F) came to her, to the bed of love, and in their lust they defiled her. After she had been defiled by them, she turned away from them in disgust.(G)

Read full chapter

Footnotes

  1. Ezekiel 23:14 Or Babylonians
  2. Ezekiel 23:15 Or Babylonia; also in verse 16

14 And that she increased her whoredoms: for when she saw men pourtrayed upon the wall, the images of the Chaldeans pourtrayed with vermilion,

15 Girded with girdles upon their loins, exceeding in dyed attire upon their heads, all of them princes to look to, after the manner of the Babylonians of Chaldea, the land of their nativity:

16 And as soon as she saw them with her eyes, she doted upon them, and sent messengers unto them into Chaldea.

17 And the Babylonians came to her into the bed of love, and they defiled her with their whoredom, and she was polluted with them, and her mind was alienated from them.

Read full chapter

Ọdún àwọn ọmọ Israẹli

23 (A)Olúwa sọ fún Mose wí pé, “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí o sì wí fún wọn pé, ‘Ìwọ̀nyí ni àwọn àjọ̀dún tí a yàn, àwọn àjọ̀dún ti Olúwa èyí tí ẹ gbọdọ̀ kéde gẹ́gẹ́ bí àjọ̀dún tí a yàn.

Ọjọ́ ìsinmi

“ ‘Ọjọ́ mẹ́fà ni ẹ le fi ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ni ọjọ́ ìsinmi. Ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn. Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan, níbikíbi tí ẹ bá ń gbé. Ọjọ́ ìsinmi Olúwa ni.

Ọdún ìrékọjá àti àkàrà aláìwú

“ ‘Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọdún tí Olúwa yàn, àjọ̀dún tí a yàn tí ẹ gbọdọ̀ kéde lákokò wọn. Àjọ ìrékọjá Olúwa bẹ̀rẹ̀ ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní (Epiri). Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù kìn-ín-ní, ni àjọ̀dún àkàrà àìwú (àkàrà tí kò ní ìwúkàrà) tí Olúwa bẹ̀rẹ̀ fún ọjọ́ méje ni ẹ gbọdọ̀ fi jẹ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà. Ní ọjọ́ kìn-ín-ní kí àpéjọ mímọ́ kí ó wà; ẹ́yin kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ agbára kankan nínú rẹ̀. Ọjọ́ méje ni kí ẹ fi mú ọrẹ tí a fi iná ṣe wá fún Olúwa. Ní ọjọ́ keje, ẹ pe ìpàdé àjọ mímọ́, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan.’ ”

Ọrẹ àkọ́so

Olúwa sọ fún Mose pe 10 “Sọ fún àwọn ará Israẹli, kí o sì wí fún wọn pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi yóò fún yín, tí ẹ bá ń ṣe ìkórè, kí ẹ mú síírí ọkà àkọ́kọ́ tí ẹ kórè wá fún àlùfáà. 11 Kí ó fi síírí ọkà náà níwájú Olúwa, kí ó le jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún yín: kí àlùfáà fì í ní ọjọ́ kejì ìsinmi. 12 Ní ọjọ́ tí ẹ bá fi síírí ọkà náà, kí ẹ mú ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan láìní àbùkù rú ẹbọ sísun sí Olúwa. 13 Pẹ̀lú ọrẹ ọkà rẹ tí ó jẹ́ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òṣùwọ̀n efa (èyí jẹ́ lítà mẹ́rin ààbọ̀) ti ìyẹ̀fun, tí a fi òróró pò ọrẹ tí a fi iná ṣe fún Olúwa òórùn dídùn pẹ̀lú ọrẹ ohun mímu rẹ̀ tí í ṣe ìdámẹ́rin òṣùwọ̀n hínì (Èyí jẹ́ lítà kan). 14 Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ àkàrà kankan tàbí kí ẹ sun ọkà tuntun títí di ọjọ́ tí ẹ fi mú ọrẹ yín wá fún Ọlọ́run yín. Èyí ni ìlànà ayérayé fún ìran tí ń bọ̀, níbikíbi tí ẹ bá ń gbé.

Ọdún àwọn ọ̀sẹ̀ Pentikosti

15 “ ‘Ẹ ka ọ̀sẹ̀ méje gbangba, láti ọjọ́ kejì ọjọ́ ìsinmi, àní ọjọ́ tí ẹ mú ìdì ọkà fífì wá. 16 Ẹ ka àádọ́ta (50) ọjọ́ títí dé ọjọ́ kejì ọ̀sẹ̀ méjèèje, kí ẹ sì mú ọrẹ ọkà tuntun wá fún Olúwa. 17 Láti ibikíbi tí ẹ bá ń gbé, ẹ mú ìṣù àkàrà méjì tí a fi òṣùwọ̀n ìdá méjì nínú mẹ́wàá tí efa (Èyí jẹ́ lítà mẹ́rin ààbọ̀) ti ìyẹ̀fun, tí a fi ìwúkàrà ṣe, gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fífì àkọ́so sí Olúwa. 18 Ẹ fi akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbùkù, ọmọ màlúù kan àti àgbò méjì kún àkàrà yìí: wọn yóò jẹ́ ẹbọ sísun sí Olúwa, pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu wọn, àní ẹbọ tí a fi iná ṣe, olóòórùn dídùn ni sí Olúwa. 19 Lẹ́yìn náà kí ẹ fi akọ ewúrẹ́ kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àti ọ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan fún ọrẹ àlàáfíà. 20 Kí àlùfáà fi ọ̀dọ́-àgùntàn méjèèjì náà níwájú Olúwa bí i ọrẹ fífì pẹ̀lú oúnjẹ àkọ́so wọn jẹ́ ọrẹ mímọ́ sí Olúwa fún àlùfáà. 21 Ní ọjọ́ yìí náà ni kí ẹ kéde ìpàdé àjọ mímọ́: ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran tí ń bọ̀ níbi yówù tí ẹ ń gbé.

22 (B)“ ‘Nígbà tí ẹ bá kórè ilẹ̀ yín ẹ má ṣe kórè dé ìkangun oko yín, tàbí kí ẹ padà gé èyí tí ó ṣẹ́kù sílẹ̀ nínú ìkórè yín. Ẹ fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn tálákà àti àwọn àlejò: Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ ”

Ọdún ìfùnpè

23 Olúwa sọ fún Mose pé 24 “Sọ fún àwọn ará Israẹli: ‘Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù keje, kí ẹ ní ọjọ́ ìsinmi, ìpàdé àjọ mímọ́ tí a fi fèrè fífọn ṣe ìrántí 25 Ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́ ojúmọ́, ṣùgbọ́n ẹ mú ọrẹ tí a fi iná sun wá síwájú Olúwa.’ ”

Ọjọ́ ètùtù

26 Olúwa sọ fún Mose pé, 27 “Ọjọ́ kẹwàá oṣù keje yìí ni ọjọ́ ètùtù. Ẹ ni ìpàdé àjọ mímọ́, kí ẹ sì ṣẹ́ ara yín kí ẹ sì mú ọrẹ tí a fi iná ṣe wá fún Olúwa. 28 Ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́ kankan ní ọjọ́ náà, torí pé ọjọ́ ètùtù ni, nínú èyí tí a ń ṣe ètùtù fún yín níwájú Olúwa Ọlọ́run yín. 29 Ẹnikẹ́ni tí kò bá ṣẹ́ ara rẹ̀ ní ọjọ́ náà ni a ó gé kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 30 Èmi yóò pa ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣiṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ náà run kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 31 Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan rárá. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran tí ń bọ̀, níbikíbi tí ẹ bá ń gbé. 32 Ọjọ́ ìsinmi ni fún un yín, ẹ gbọdọ̀ ṣẹ́ ara yín, láti ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹsànán oṣù náà, títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ tí ó tẹ̀lé e, ni kí ẹ fi sinmi.”

Ọdún àgọ́

33 (C)Olúwa sọ fún Mose pé, 34 “Sọ fún àwọn ará Israẹli pé: ‘Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù keje ni kí àjọ̀dún ọdún àgọ́ ti Olúwa bẹ̀rẹ̀ kí ó sì wà títí di ọjọ́ méje. 35 Ọjọ́ kìn-ín-ní jẹ́ ọjọ́ ìpàdé mímọ́: Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ ojúmọ́. 36 Ọjọ́ méje ni kí ẹ fi mú ọrẹ tí a fi iná ṣe wá, ní ọjọ́ kẹjọ, ẹ pe ìpàdé mímọ́ kí ẹ sì mú ọrẹ tí a fi iná ṣe wá fún Olúwa, èyí jẹ́ ìpàdé tí ó gbẹ̀yìn; ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́ ojoojúmọ́.

37 (“ ‘Ìwọ̀nyí ni àwọn àjọ̀dún tí Olúwa ti yàn tí ẹ gbọdọ̀ kéde gẹ́gẹ́ bí i àjọ̀dún tí a yàn fún mímu àwọn ọrẹ tí a fi iná ṣe sí Olúwa wá—ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà, ọrẹ ẹbọ àti ọrẹ ohun mímu, fún ọjọ́ kọ̀ọ̀kan: 38 Àwọn ọrẹ wọ̀nyí wà ní àfikún pẹ̀lú àwọn ọrẹ ọjọ́ ìsinmi Olúwa, àti pẹ̀lú ẹ̀bùn yín àti ohunkóhun tí ẹ ti jẹ́ ẹ̀jẹ́ àti gbogbo ọrẹ àtinúwá yín fún Olúwa.)

39 “ ‘Torí náà, bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù keje lẹ́yìn ìgbà tí ẹ ti kórè ilẹ̀ náà, ẹ ṣe àjọ̀dún yìí fún Olúwa ní ọjọ́ méje. Ọjọ́ kìn-ín-ní jẹ́ ọjọ́ ìsinmi, ọjọ́ kẹjọ pẹ̀lú si tún jẹ́ ọjọ́ ìsinmi. 40 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, kí ẹ mú àṣàyàn èso láti orí igi dáradára, imọ̀ ọ̀pẹ, àti ẹ̀ka igi tó rúwé, àti igi wílò odò, kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín fún ọjọ́ méje. 41 Ẹ ṣe èyí ní àjọ̀dún sí Olúwa fún ọjọ́ méje lọ́dọọdún. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran tí ń bọ̀: Ẹ ṣe é ní oṣù keje. 42 Ẹ gbé inú àgọ́ fún ọjọ́ méje. Kí gbogbo ọmọ bíbí Israẹli gbé nínú àgọ́. 43 Kí àwọn ìran yín le mọ̀ pé mo mú kí Israẹli gbé nínú àgọ́, nígbà tí mo mú wọn jáde ní Ejibiti. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ ”

44 Báyìí ni Mose kéde àwọn àjọ̀dún tí a yàn Olúwa fún àwọn ọmọ Israẹli.

The Appointed Festivals

23 The Lord said to Moses, “Speak to the Israelites and say to them: ‘These are my appointed festivals,(A) the appointed festivals of the Lord, which you are to proclaim as sacred assemblies.(B)

The Sabbath

“‘There are six days when you may work,(C) but the seventh day is a day of sabbath rest,(D) a day of sacred assembly. You are not to do any work;(E) wherever you live, it is a sabbath to the Lord.

The Passover and the Festival of Unleavened Bread(F)

“‘These are the Lord’s appointed festivals, the sacred assemblies you are to proclaim at their appointed times:(G) The Lord’s Passover(H) begins at twilight on the fourteenth day of the first month.(I) On the fifteenth day of that month the Lord’s Festival of Unleavened Bread(J) begins; for seven days(K) you must eat bread made without yeast. On the first day hold a sacred assembly(L) and do no regular work. For seven days present a food offering to the Lord.(M) And on the seventh day hold a sacred assembly and do no regular work.’”

Offering the Firstfruits

The Lord said to Moses, 10 “Speak to the Israelites and say to them: ‘When you enter the land I am going to give you(N) and you reap its harvest,(O) bring to the priest a sheaf(P) of the first grain you harvest.(Q) 11 He is to wave the sheaf before the Lord(R) so it will be accepted(S) on your behalf; the priest is to wave it on the day after the Sabbath. 12 On the day you wave the sheaf, you must sacrifice as a burnt offering to the Lord a lamb a year old(T) without defect,(U) 13 together with its grain offering(V) of two-tenths of an ephah[a](W) of the finest flour mixed with olive oil—a food offering presented to the Lord, a pleasing aroma—and its drink offering(X) of a quarter of a hin[b] of wine.(Y) 14 You must not eat any bread, or roasted or new grain,(Z) until the very day you bring this offering to your God.(AA) This is to be a lasting ordinance for the generations to come,(AB) wherever you live.(AC)

The Festival of Weeks(AD)

15 “‘From the day after the Sabbath, the day you brought the sheaf of the wave offering, count off seven full weeks. 16 Count off fifty days up to the day after the seventh Sabbath,(AE) and then present an offering of new grain to the Lord. 17 From wherever you live, bring two loaves made of two-tenths of an ephah(AF) of the finest flour, baked with yeast, as a wave offering of firstfruits(AG) to the Lord. 18 Present with this bread seven male lambs, each a year old and without defect, one young bull and two rams. They will be a burnt offering to the Lord, together with their grain offerings and drink offerings(AH)—a food offering, an aroma pleasing to the Lord. 19 Then sacrifice one male goat for a sin offering[c] and two lambs, each a year old, for a fellowship offering. 20 The priest is to wave the two lambs before the Lord as a wave offering,(AI) together with the bread of the firstfruits. They are a sacred offering to the Lord for the priest. 21 On that same day you are to proclaim a sacred assembly(AJ) and do no regular work.(AK) This is to be a lasting ordinance for the generations to come, wherever you live.

22 “‘When you reap the harvest(AL) of your land, do not reap to the very edges of your field or gather the gleanings of your harvest.(AM) Leave them for the poor and for the foreigner residing among you.(AN) I am the Lord your God.’”

The Festival of Trumpets(AO)

23 The Lord said to Moses, 24 “Say to the Israelites: ‘On the first day of the seventh month you are to have a day of sabbath rest, a sacred assembly(AP) commemorated with trumpet blasts.(AQ) 25 Do no regular work,(AR) but present a food offering to the Lord.(AS)’”

The Day of Atonement(AT)

26 The Lord said to Moses, 27 “The tenth day of this seventh month(AU) is the Day of Atonement.(AV) Hold a sacred assembly(AW) and deny yourselves,[d] and present a food offering to the Lord. 28 Do not do any work(AX) on that day, because it is the Day of Atonement, when atonement is made for you before the Lord your God. 29 Those who do not deny themselves on that day must be cut off from their people.(AY) 30 I will destroy from among their people(AZ) anyone who does any work on that day. 31 You shall do no work at all. This is to be a lasting ordinance(BA) for the generations to come, wherever you live. 32 It is a day of sabbath rest(BB) for you, and you must deny yourselves. From the evening of the ninth day of the month until the following evening you are to observe your sabbath.”(BC)

The Festival of Tabernacles(BD)

33 The Lord said to Moses, 34 “Say to the Israelites: ‘On the fifteenth day of the seventh(BE) month the Lord’s Festival of Tabernacles(BF) begins, and it lasts for seven days. 35 The first day is a sacred assembly;(BG) do no regular work.(BH) 36 For seven days present food offerings to the Lord, and on the eighth day hold a sacred assembly(BI) and present a food offering to the Lord.(BJ) It is the closing special assembly; do no regular work.

37 (“‘These are the Lord’s appointed festivals, which you are to proclaim as sacred assemblies for bringing food offerings to the Lord—the burnt offerings and grain offerings, sacrifices and drink offerings(BK) required for each day. 38 These offerings(BL) are in addition to those for the Lord’s Sabbaths(BM) and[e] in addition to your gifts and whatever you have vowed and all the freewill offerings(BN) you give to the Lord.)

39 “‘So beginning with the fifteenth day of the seventh month, after you have gathered the crops of the land, celebrate the festival(BO) to the Lord for seven days;(BP) the first day is a day of sabbath rest, and the eighth day also is a day of sabbath rest. 40 On the first day you are to take branches(BQ) from luxuriant trees—from palms, willows and other leafy trees(BR)—and rejoice(BS) before the Lord your God for seven days. 41 Celebrate this as a festival to the Lord for seven days each year. This is to be a lasting ordinance for the generations to come; celebrate it in the seventh month. 42 Live in temporary shelters(BT) for seven days: All native-born Israelites are to live in such shelters 43 so your descendants will know(BU) that I had the Israelites live in temporary shelters when I brought them out of Egypt. I am the Lord your God.’”

44 So Moses announced to the Israelites the appointed festivals of the Lord.

Footnotes

  1. Leviticus 23:13 That is, probably about 7 pounds or about 3.2 kilograms; also in verse 17
  2. Leviticus 23:13 That is, about 1 quart or about 1 liter
  3. Leviticus 23:19 Or purification offering
  4. Leviticus 23:27 Or and fast; similarly in verses 29 and 32
  5. Leviticus 23:38 Or These festivals are in addition to the Lord’s Sabbaths, and these offerings are

23 And the Lord spake unto Moses, saying,

Speak unto the children of Israel, and say unto them, Concerning the feasts of the Lord, which ye shall proclaim to be holy convocations, even these are my feasts.

Six days shall work be done: but the seventh day is the sabbath of rest, an holy convocation; ye shall do no work therein: it is the sabbath of the Lord in all your dwellings.

These are the feasts of the Lord, even holy convocations, which ye shall proclaim in their seasons.

In the fourteenth day of the first month at even is the Lord's passover.

And on the fifteenth day of the same month is the feast of unleavened bread unto the Lord: seven days ye must eat unleavened bread.

In the first day ye shall have an holy convocation: ye shall do no servile work therein.

But ye shall offer an offering made by fire unto the Lord seven days: in the seventh day is an holy convocation: ye shall do no servile work therein.

And the Lord spake unto Moses, saying,

10 Speak unto the children of Israel, and say unto them, When ye be come into the land which I give unto you, and shall reap the harvest thereof, then ye shall bring a sheaf of the firstfruits of your harvest unto the priest:

11 And he shall wave the sheaf before the Lord, to be accepted for you: on the morrow after the sabbath the priest shall wave it.

12 And ye shall offer that day when ye wave the sheaf an he lamb without blemish of the first year for a burnt offering unto the Lord.

13 And the meat offering thereof shall be two tenth deals of fine flour mingled with oil, an offering made by fire unto the Lord for a sweet savour: and the drink offering thereof shall be of wine, the fourth part of an hin.

14 And ye shall eat neither bread, nor parched corn, nor green ears, until the selfsame day that ye have brought an offering unto your God: it shall be a statute for ever throughout your generations in all your dwellings.

15 And ye shall count unto you from the morrow after the sabbath, from the day that ye brought the sheaf of the wave offering; seven sabbaths shall be complete:

16 Even unto the morrow after the seventh sabbath shall ye number fifty days; and ye shall offer a new meat offering unto the Lord.

17 Ye shall bring out of your habitations two wave loaves of two tenth deals; they shall be of fine flour; they shall be baken with leaven; they are the firstfruits unto the Lord.

18 And ye shall offer with the bread seven lambs without blemish of the first year, and one young bullock, and two rams: they shall be for a burnt offering unto the Lord, with their meat offering, and their drink offerings, even an offering made by fire, of sweet savour unto the Lord.

19 Then ye shall sacrifice one kid of the goats for a sin offering, and two lambs of the first year for a sacrifice of peace offerings.

20 And the priest shall wave them with the bread of the firstfruits for a wave offering before the Lord, with the two lambs: they shall be holy to the Lord for the priest.

21 And ye shall proclaim on the selfsame day, that it may be an holy convocation unto you: ye shall do no servile work therein: it shall be a statute for ever in all your dwellings throughout your generations.

22 And when ye reap the harvest of your land, thou shalt not make clean riddance of the corners of thy field when thou reapest, neither shalt thou gather any gleaning of thy harvest: thou shalt leave them unto the poor, and to the stranger: I am the Lord your God.

23 And the Lord spake unto Moses, saying,

24 Speak unto the children of Israel, saying, In the seventh month, in the first day of the month, shall ye have a sabbath, a memorial of blowing of trumpets, an holy convocation.

25 Ye shall do no servile work therein: but ye shall offer an offering made by fire unto the Lord.

26 And the Lord spake unto Moses, saying,

27 Also on the tenth day of this seventh month there shall be a day of atonement: it shall be an holy convocation unto you; and ye shall afflict your souls, and offer an offering made by fire unto the Lord.

28 And ye shall do no work in that same day: for it is a day of atonement, to make an atonement for you before the Lord your God.

29 For whatsoever soul it be that shall not be afflicted in that same day, he shall be cut off from among his people.

30 And whatsoever soul it be that doeth any work in that same day, the same soul will I destroy from among his people.

31 Ye shall do no manner of work: it shall be a statute for ever throughout your generations in all your dwellings.

32 It shall be unto you a sabbath of rest, and ye shall afflict your souls: in the ninth day of the month at even, from even unto even, shall ye celebrate your sabbath.

33 And the Lord spake unto Moses, saying,

34 Speak unto the children of Israel, saying, The fifteenth day of this seventh month shall be the feast of tabernacles for seven days unto the Lord.

35 On the first day shall be an holy convocation: ye shall do no servile work therein.

36 Seven days ye shall offer an offering made by fire unto the Lord: on the eighth day shall be an holy convocation unto you; and ye shall offer an offering made by fire unto the Lord: it is a solemn assembly; and ye shall do no servile work therein.

37 These are the feasts of the Lord, which ye shall proclaim to be holy convocations, to offer an offering made by fire unto the Lord, a burnt offering, and a meat offering, a sacrifice, and drink offerings, every thing upon his day:

38 Beside the sabbaths of the Lord, and beside your gifts, and beside all your vows, and beside all your freewill offerings, which ye give unto the Lord.

39 Also in the fifteenth day of the seventh month, when ye have gathered in the fruit of the land, ye shall keep a feast unto the Lord seven days: on the first day shall be a sabbath, and on the eighth day shall be a sabbath.

40 And ye shall take you on the first day the boughs of goodly trees, branches of palm trees, and the boughs of thick trees, and willows of the brook; and ye shall rejoice before the Lord your God seven days.

41 And ye shall keep it a feast unto the Lord seven days in the year. It shall be a statute for ever in your generations: ye shall celebrate it in the seventh month.

42 Ye shall dwell in booths seven days; all that are Israelites born shall dwell in booths:

43 That your generations may know that I made the children of Israel to dwell in booths, when I brought them out of the land of Egypt: I am the Lord your God.

44 And Moses declared unto the children of Israel the feasts of the Lord.

Ọrẹ ojoojúmọ́

28 Olúwa sọ fún Mose pé, “Fún àwọn ọmọ Israẹli ní òfin yìí kí o sì wí fún wọn pé: ‘Ẹ rí i wí pé ẹ gbé e wá sí iwájú mi ní àkókò tí a ti yàn, oúnjẹ ọrẹ ẹbọ mi tí a fi iná ṣe sí mi, gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí mi.’ (A)Sọ fún wọn, ‘Èyí ní ọrẹ ẹbọ tí a fi iná sun tí ẹ gbọdọ̀ mú wá fún Olúwa: akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan aláìlábàwọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sísun ní ojoojúmọ́. Pèsè ọ̀dọ́-àgùntàn kan ní òwúrọ̀ àti òmíràn ní àfẹ̀mọ́júmọ́. Pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ tí ó jẹ́ ìdámẹ́wàá efa ìyẹ̀fun dáradára tí a pò mọ́ ìdámẹ́rin hínì òróró tí a yọ lára Olifi. Èyí ni ẹbọ sísun gbogbo ìgbà tí a fi lélẹ̀ ní òkè Sinai gẹ́gẹ́ bí olóòórùn dídùn ẹbọ tí a fi iná sun fún Olúwa pẹ̀lú iná. Àfikún ọrẹ ohun mímu rẹ gbọdọ̀ jẹ́ ìdámẹ́rin ti hínì dídé omi mímu tí ó kan pẹ̀lú ọ̀kọ̀ọ̀kan ọ̀dọ́-àgùntàn. Da ẹbọ mímu náà síta sí Olúwa ní ibi mímọ́. Pèsè ọ̀dọ́-àgùntàn kejì ní àfẹ̀mọ́júmọ́, pẹ̀lú oríṣìí ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu èyí tí ó pèsè ní òwúrọ̀, èyí ni ẹbọ tí a fi iná ṣe, olóòórùn dídùn sí Olúwa.

Ẹbọ ọjọ́ ìsinmi

“ ‘Ní ọjọ́ ìsinmi, pèsè akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan tí kò lábùkù, pẹ̀lú ẹbọ ohun mímu àti ẹbọ ohun jíjẹ tí i ṣe ìdá méjì nínú ìdámẹ́wàá òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò. 10 Èyí ni ẹbọ sísun fún gbogbo ọjọ́ ìsinmi kọ̀ọ̀kan, ní àfikún pẹ̀lú ẹbọ sísun àti ẹbọ ohun mímu.

Ẹbọ oṣooṣù

11 “ ‘Àti ní ọjọ́ tí o bẹ̀rẹ̀ oṣù kọ̀ọ̀kan, kí ẹ̀yin kí ó gbé ẹbọ sísun fún Olúwa pẹ̀lú ọ̀dọ́ akọ màlúù méjì, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, kí gbogbo rẹ̀ sì jẹ́ aláìlábùkù. 12 Pẹ̀lú akọ màlúù kọ̀ọ̀kan ni kí wọn ó rú ẹbọ ohun jíjẹ ẹbọ ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá ìyẹ̀fun tí a pòpọ̀ pẹ̀lú òróró; pẹ̀lú àgbò, ni kí wọn ó rú ẹbọ ohun jíjẹ tí í ṣe ìdá méjì nínú mẹ́wàá òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun tí a pòpọ̀ mọ́ òróró; 13 pẹ̀lú ọ̀kọ̀ọ̀kan ọ̀dọ́-àgùntàn, ni kí ẹ rú ẹbọ ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a pò mọ́ òróró. Èyí ni ẹbọ sísun, òórùn dídùn, àti ẹbọ tí a ṣe fún Olúwa pẹ̀lú iná. 14 Kí ẹbọ ohun mímu wọn jẹ́ ààbọ̀ òṣùwọ̀n hínì ti ọtí wáìnì, fún akọ màlúù kan, àti ìdámẹ́wàá òṣùwọ̀n hínì fún àgbò kan àti ìdámẹ́rin òṣùwọ̀n hínì fún ọ̀dọ́-àgùntàn kan. Èyí ni ẹbọ sísun tí wọn ó máa rú ní oṣù kọ̀ọ̀kan nínú ọdún. 15 Yàtọ̀ sí ẹbọ sísun pẹ̀lú ẹbọ ohun mímu, ẹ gbọdọ̀ fi akọ ewúrẹ́ kọ̀ọ̀kan fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.

Àjọ ìrékọjá

16 (B)“ ‘Ní ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní ni ìrékọjá Olúwa gbọdọ̀ wáyé. 17 (C)Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù yìí ẹ gbọdọ̀ ṣiṣẹ́ àjọ̀dún fún ọjọ́ méje kí ó jẹ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà. 18 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní kí àpéjọ mímọ́ kí ó wà; ẹ́yin kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ agbára kankan. 19 Ẹ rú ẹbọ sísun sí Olúwa, ẹ rú u pẹ̀lú ọ̀dọ́ màlúù méjì akọ, ẹbọ sísun pẹ̀lú iná àgbò kan àti ọ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan kí wọn kí ó jẹ́ aláìlábùkù. 20 Pẹ̀lú akọ màlúù kọ̀ọ̀kan ni kí ẹ pèsè ẹbọ ohun mímu pẹ̀lú ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò; pẹ̀lú àgbò, ìdá méjì nínú mẹ́wàá; 21 pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan ìdákan nínú mẹ́wàá. 22 Pẹ̀lú òbúkọ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣètùtù fún un yín. 23 Ṣe eléyìí ní àfikún sí ẹbọ sísun àràárọ̀. 24 Báyìí ní kí ẹ̀yin rúbọ ní ọjọọjọ́, jálẹ̀ ní ọjọ́ méjèèje, oúnjẹ ẹbọ tí a fi iná ṣe, tí olóòórùn dídùn sí Olúwa; ó rú u pẹ̀lú ẹbọ sísun ìgbà gbogbo, àti ẹbọ ohun mímu. 25 Ní ọjọ́ keje kí ẹ̀yin kí ó ní àpéjọ mímọ́, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan.

Àjọ ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀

26 (D)“ ‘Ní ọjọ́ àkọ́so pẹ̀lú, nígbà tí ẹ̀yin bá mú ẹbọ ohun jíjẹ tuntun wá fún Olúwa lẹ́yìn àsìkò àjọ̀dún, kí ẹ̀yin kí ó ní àpéjọ mímọ́, ẹ̀yin kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. 27 Kí ẹ mú ẹbọ sísun ẹgbọrọ màlúù méjì, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kan gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn fún Olúwa. 28 Pẹ̀lú ọ̀kọ̀ọ̀kan akọ màlúù ní kí ẹ rú ẹbọ ohun mímu ìdámẹ́ta pẹ̀lú òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò pẹ̀lú àgbò kan. 29 Àti pẹ̀lú ọ̀kọ̀ọ̀kan ọ̀dọ́-àgùntàn méje, kí ó jẹ́ ìdákan nínú mẹ́wàá. 30 Ẹ fi òbúkọ kan ṣe ètùtù fún ara yín. 31 Kí ẹ̀yin kí ó rú wọn pẹ̀lú ẹbọ sísun ìgbà gbogbo, àti ẹbọ ohun mímu yín àti ẹbọ ohun jíjẹ yín. Kí ẹ sì ri dájú pé àwọn ẹranko náà jẹ́ aláìlábùkù.

Àsè ìpè

29 (E)“ ‘Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù keje, kí ẹ ní àpéjọ mímọ́, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Ọjọ́ ìfùnpè ni ó jẹ́ fún yín. Gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa, ẹ pèsè ẹgbọrọ akọ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan aláìlábùkù, kí ẹ fi ẹbọ sísun. Pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ wọn, ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òṣùwọ̀n fún akọ màlúù kan, àti ìdá méjì nínú mẹ́wàá, òṣùwọ̀n fún àgbò kan, àti ìdámẹ́wàá òṣùwọ̀n fún ọ̀dọ́-àgùntàn kan, àti fún ọ̀dọ́-àgùntàn méje. Àti òbúkọ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣètùtù fún yín. Pẹ̀lú ẹbọ sísun oṣù àti ẹbọ ohun jíjẹ rẹ̀ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo àti ẹbọ mímu wọn gẹ́gẹ́ bí ìlànà wọn. Fún òórùn dídùn, ẹbọ tí a fi iná ṣe sí Olúwa.

Ọjọ́ ẹbọ ètùtù

(F)“ ‘Ní ọjọ́ kẹwàá nínú oṣù keje, kí ẹ ṣe àpéjọ mímọ́. Kí ẹ̀yin kí ó sẹ́ ara yín, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Kí ẹ̀yin kí ó rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí Olúwa, ẹgbọrọ akọ màlúù kan, àgbò kan, àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kan, kí wọn kí ó sì jẹ́ aláìlábùkù fún yín. Pẹ̀lú akọ màlúù, pèsè ọrẹ ìdámẹ́wàá mẹ́ta, òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò àti ìdámẹ́wàá méjì òṣùwọ̀n fún àgbò kan, 10 àti fún ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan, ìdámẹ́wàá òṣùwọ̀n. 11 Pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, pẹ̀lú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ fún ètùtù àti ẹbọ sísun gbogbo ìgbà àti ẹbọ jíjẹ rẹ̀ àti ẹbọ mímu wọn.

Àpèjẹ Àgọ́

12 (G)“ ‘Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù keje, kí ẹ̀yin kí ó ní àpéjọ mímọ́, ẹ̀yin kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Kí ẹ̀yin kí ó sì ṣe àjọyọ̀ fún Olúwa fún ọjọ́ méje. 13 Kí ẹ sì rú ẹbọ sísun kan, ẹbọ tí a fi iná ṣe, tí ó ní òórùn dídùn sí Olúwa, ẹbọ tí ẹgbọrọ akọ màlúù mẹ́tàlá, àgbò méjì àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́rìnlá tí ó jẹ́ ọdún kan, tí gbogbo rẹ̀ sì jẹ́ aláìlábùkù. 14 Àti ẹbọ ohun jíjẹ wọn, ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò, ìdámẹ́wàá mẹ́ta òṣùwọ̀n fún akọ màlúù kan, bẹ́ẹ̀ ni fún akọ màlúù mẹ́tẹ̀ẹ̀tàlá, ìdámẹ́wàá méjì òṣùwọ̀n fún àgbò kan, bẹ́ẹ̀ ni fún àgbò méjèèjì, 15 àti fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ọ̀dọ́-àgùntàn kan. Bẹ́ẹ̀ ni fún ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́rẹ̀ẹ̀rìnlá. 16 Àti akọ ewúrẹ́ kan gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, pẹ̀lú ẹbọ sísun gbogbo ìgbà ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu rẹ̀.

17 “ ‘Àti ní ọjọ́ kejì ni kí ẹ̀yin kí ó fi ẹgbọrọ akọ màlúù méjìlá, àgbò méjì àti ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́rìnlá ọlọ́dún kan aláìlábùkù rú ẹbọ. 18 Pẹ̀lú fún akọ màlúù, fún àgbò, àti fún ọ̀dọ́-àgùntàn kí ẹ pe ẹbọ ohun jíjẹ, àti ẹbọ ohun mímu, kí ó jẹ́ bí iye wọn, gẹ́gẹ́ bí ìlànà. 19 Àti òbúkọ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀lú ẹbọ sísun gbogbo ìgbà pẹ̀lú ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu.

20 “ ‘Ní ọjọ́ kẹta, pèsè akọ màlúù mọ́kànlá, àgbò méjì, akọ àgùntàn mẹ́rìnlá ti ọdún kan tí kò ní àbùkù. 21 Pẹ̀lú akọ màlúù, àgbò, àti akọ àgùntàn, pèsè ọrẹ ohun jíjẹ àti ohun mímu gẹ́gẹ́ bí iye wọn. 22 Pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo pẹ̀lú ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ mímu.

23 “ ‘Ní ọjọ́ kẹrin, pèsè akọ màlúù mẹ́wàá, àgbò méjì, àti ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́rìnlá ti ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbùkù. 24 Àti akọ màlúù, àgbò àti àgùntàn, pèsè ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ mímu gẹ́gẹ́ bí iye wọn, gẹ́gẹ́ bí ìlànà. 25 Àti akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀lú ẹbọ sísun gbogbo ìgbà, pẹ̀lú ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu.

26 “ ‘Àti ní ọjọ́ karùn-ún, pèsè akọ màlúù mẹ́sàn-án, àgbò méjì àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́rìnlá ti ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, tí gbogbo rẹ̀ kò ní àbùkù. 27 Pẹ̀lú akọ màlúù, àgbò àti ọ̀dọ́-àgùntàn, pèsè ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí iye wọn sí ìlànà. 28 Àti akọ ewúrẹ́ kan gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀lú ẹbọ sísun ìgbà gbogbo pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu.

29 “ ‘Ní ọjọ́ kẹfà, pèsè akọ màlúù mẹ́jọ, àgbò ọlọ́dún kan tí gbogbo rẹ̀ kò ní àbùkù. 30 Pẹ̀lú akọ màlúù, àgbò, àti ọ̀dọ́-àgùntàn, pèsè ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí iye wọn. 31 Pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ kan gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, pẹ̀lú ẹbọ sísun gbogbo ìgbà pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu.

32 “ ‘Àti ní ọjọ́ keje, pèsè akọ màlúù méje, àgbò méjì, àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́rìnlá ti ọlọ́dún kan, tí gbogbo rẹ̀ kò sì ní àbùkù. 33 Pẹ̀lú akọ màlúù, àgbò, àti ọ̀dọ́-àgùntàn, pèsè ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu fún wọn gẹ́gẹ́ bí iye wọn. 34 Pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, pẹ̀lú ẹbọ sísun gbogbo ìgbà, pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu.

35 (H)“ ‘Àti ní ọjọ́ kẹjọ kí ẹ̀yin kó ní àpéjọ, kí ẹ má sì ṣe iṣẹ́ kankan. 36 Kí ẹ̀yin ṣe ìgbékalẹ̀ ẹbọ tí a fi iná ṣe tí ó ní òórùn dídùn sí Olúwa, ẹbọ sísun ti akọ màlúù kan, àgbò ọlọ́dún kan àti ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan méje, gbogbo rẹ̀ tí kò ní àbùkù. 37 Pẹ̀lú akọ màlúù, àgbò, àti ọ̀dọ́-àgùntàn, pèsè fún wọn ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí iye wọn. 38 Àti akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀lú ẹbọ sísun gbogbo ìgbà àti ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu.

39 “ ‘Pẹ̀lú ẹ̀jẹ́ yín, àti ẹbọ àtinúwá yín, kí ẹ̀yin kí o pèsè fún Olúwa ní àjọ̀dún tí a yàn yín, ẹbọ sísun, ẹbọ ohun jíjẹ, ẹbọ ohun mímu àti ẹbọ ìkẹ́gbẹ́ yín.’ ”

40 Mose sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli gbogbo ohun tí Olúwa ti pàṣẹ fún un.

Daily Offerings

28 The Lord said to Moses, “Give this command to the Israelites and say to them: ‘Make sure that you present to me at the appointed time(A) my food(B) offerings, as an aroma pleasing to me.’(C) Say to them: ‘This is the food offering you are to present to the Lord: two lambs a year old without defect,(D) as a regular burnt offering each day.(E) Offer one lamb in the morning and the other at twilight,(F) together with a grain offering(G) of a tenth of an ephah[a] of the finest flour(H) mixed with a quarter of a hin[b] of oil(I) from pressed olives. This is the regular burnt offering(J) instituted at Mount Sinai(K) as a pleasing aroma, a food offering presented to the Lord.(L) The accompanying drink offering(M) is to be a quarter of a hin of fermented drink(N) with each lamb. Pour out the drink offering to the Lord at the sanctuary.(O) Offer the second lamb at twilight,(P) along with the same kind of grain offering and drink offering that you offer in the morning.(Q) This is a food offering, an aroma pleasing to the Lord.(R)

Sabbath Offerings

“‘On the Sabbath(S) day, make an offering of two lambs a year old without defect,(T) together with its drink offering and a grain offering of two-tenths of an ephah[c](U) of the finest flour mixed with olive oil.(V) 10 This is the burnt offering for every Sabbath,(W) in addition to the regular burnt offering(X) and its drink offering.

Monthly Offerings

11 “‘On the first of every month,(Y) present to the Lord a burnt offering of two young bulls,(Z) one ram(AA) and seven male lambs a year old, all without defect.(AB) 12 With each bull there is to be a grain offering(AC) of three-tenths of an ephah[d](AD) of the finest flour mixed with oil; with the ram, a grain offering of two-tenths(AE) of an ephah of the finest flour mixed with oil; 13 and with each lamb, a grain offering(AF) of a tenth(AG) of an ephah of the finest flour mixed with oil. This is for a burnt offering,(AH) a pleasing aroma, a food offering presented to the Lord.(AI) 14 With each bull there is to be a drink offering(AJ) of half a hin[e] of wine; with the ram, a third of a hin[f]; and with each lamb, a quarter of a hin. This is the monthly burnt offering to be made at each new moon(AK) during the year. 15 Besides the regular burnt offering(AL) with its drink offering, one male goat(AM) is to be presented to the Lord as a sin offering.[g](AN)

The Passover(AO)

16 “‘On the fourteenth day of the first month the Lord’s Passover(AP) is to be held. 17 On the fifteenth day of this month there is to be a festival; for seven days(AQ) eat bread made without yeast.(AR) 18 On the first day hold a sacred assembly and do no regular work.(AS) 19 Present to the Lord a food offering(AT) consisting of a burnt offering of two young bulls, one ram and seven male lambs a year old, all without defect.(AU) 20 With each bull offer a grain offering of three-tenths of an ephah(AV) of the finest flour mixed with oil; with the ram, two-tenths;(AW) 21 and with each of the seven lambs, one-tenth.(AX) 22 Include one male goat as a sin offering(AY) to make atonement for you.(AZ) 23 Offer these in addition to the regular morning burnt offering. 24 In this way present the food offering every day for seven days as an aroma pleasing to the Lord;(BA) it is to be offered in addition to the regular burnt offering and its drink offering. 25 On the seventh day hold a sacred assembly and do no regular work.

The Festival of Weeks(BB)

26 “‘On the day of firstfruits,(BC) when you present to the Lord an offering of new grain during the Festival of Weeks,(BD) hold a sacred assembly and do no regular work.(BE) 27 Present a burnt offering of two young bulls, one ram and seven male lambs a year old as an aroma pleasing to the Lord.(BF) 28 With each bull there is to be a grain offering of three-tenths of an ephah of the finest flour mixed with oil; with the ram, two-tenths;(BG) 29 and with each of the seven lambs, one-tenth.(BH) 30 Include one male goat(BI) to make atonement for you. 31 Offer these together with their drink offerings, in addition to the regular burnt offering(BJ) and its grain offering. Be sure the animals are without defect.

The Festival of Trumpets(BK)

29 “‘On the first day of the seventh month hold a sacred assembly and do no regular work.(BL) It is a day for you to sound the trumpets. As an aroma pleasing to the Lord,(BM) offer a burnt offering(BN) of one young bull, one ram and seven male lambs a year old,(BO) all without defect.(BP) With the bull offer a grain offering(BQ) of three-tenths of an ephah[h] of the finest flour mixed with olive oil; with the ram, two-tenths[i]; and with each of the seven lambs, one-tenth.[j](BR) Include one male goat(BS) as a sin offering[k] to make atonement for you. These are in addition to the monthly(BT) and daily burnt offerings(BU) with their grain offerings(BV) and drink offerings(BW) as specified. They are food offerings presented to the Lord, a pleasing aroma.(BX)

The Day of Atonement(BY)

“‘On the tenth day of this seventh month hold a sacred assembly. You must deny yourselves[l](BZ) and do no work.(CA) Present as an aroma pleasing to the Lord a burnt offering of one young bull, one ram and seven male lambs a year old, all without defect.(CB) With the bull offer a grain offering(CC) of three-tenths of an ephah of the finest flour mixed with oil; with the ram, two-tenths;(CD) 10 and with each of the seven lambs, one-tenth.(CE) 11 Include one male goat(CF) as a sin offering, in addition to the sin offering for atonement and the regular burnt offering(CG) with its grain offering, and their drink offerings.(CH)

The Festival of Tabernacles(CI)

12 “‘On the fifteenth day of the seventh(CJ) month,(CK) hold a sacred assembly and do no regular work. Celebrate a festival to the Lord for seven days. 13 Present as an aroma pleasing to the Lord(CL) a food offering consisting of a burnt offering of thirteen young bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect.(CM) 14 With each of the thirteen bulls offer a grain offering(CN) of three-tenths of an ephah of the finest flour mixed with oil; with each of the two rams, two-tenths; 15 and with each of the fourteen lambs, one-tenth.(CO) 16 Include one male goat as a sin offering,(CP) in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.(CQ)

17 “‘On the second day(CR) offer twelve young bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect.(CS) 18 With the bulls, rams and lambs, offer their grain offerings(CT) and drink offerings(CU) according to the number specified.(CV) 19 Include one male goat as a sin offering,(CW) in addition to the regular burnt offering(CX) with its grain offering, and their drink offerings.(CY)

20 “‘On the third day offer eleven bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect.(CZ) 21 With the bulls, rams and lambs, offer their grain offerings and drink offerings according to the number specified.(DA) 22 Include one male goat as a sin offering, in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.

23 “‘On the fourth day offer ten bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect. 24 With the bulls, rams and lambs, offer their grain offerings and drink offerings according to the number specified. 25 Include one male goat as a sin offering, in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.

26 “‘On the fifth day offer nine bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect. 27 With the bulls, rams and lambs, offer their grain offerings and drink offerings according to the number specified. 28 Include one male goat as a sin offering, in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.

29 “‘On the sixth day offer eight bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect. 30 With the bulls, rams and lambs, offer their grain offerings and drink offerings according to the number specified. 31 Include one male goat as a sin offering, in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.

32 “‘On the seventh day offer seven bulls, two rams and fourteen male lambs a year old, all without defect. 33 With the bulls, rams and lambs, offer their grain offerings and drink offerings according to the number specified. 34 Include one male goat as a sin offering, in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.

35 “‘On the eighth day hold a closing special assembly(DB) and do no regular work. 36 Present as an aroma pleasing to the Lord(DC) a food offering consisting of a burnt offering of one bull, one ram and seven male lambs a year old,(DD) all without defect. 37 With the bull, the ram and the lambs, offer their grain offerings and drink offerings according to the number specified. 38 Include one male goat as a sin offering, in addition to the regular burnt offering with its grain offering and drink offering.

39 “‘In addition to what you vow(DE) and your freewill offerings,(DF) offer these to the Lord at your appointed festivals:(DG) your burnt offerings,(DH) grain offerings, drink offerings and fellowship offerings.(DI)’”

40 Moses told the Israelites all that the Lord commanded him.[m]

Footnotes

  1. Numbers 28:5 That is, probably about 3 1/2 pounds or about 1.6 kilograms; also in verses 13, 21 and 29
  2. Numbers 28:5 That is, about 1 quart or about 1 liter; also in verses 7 and 14
  3. Numbers 28:9 That is, probably about 7 pounds or about 3.2 kilograms; also in verses 12, 20 and 28
  4. Numbers 28:12 That is, probably about 11 pounds or about 5 kilograms; also in verses 20 and 28
  5. Numbers 28:14 That is, about 2 quarts or about 1.9 liters
  6. Numbers 28:14 That is, about 1 1/3 quarts or about 1.3 liters
  7. Numbers 28:15 Or purification offering; also in verse 22
  8. Numbers 29:3 That is, probably about 11 pounds or about 5 kilograms; also in verses 9 and 14
  9. Numbers 29:3 That is, probably about 7 pounds or about 3.2 kilograms; also in verses 9 and 14
  10. Numbers 29:4 That is, probably about 3 1/2 pounds or about 1.6 kilograms; also in verses 10 and 15
  11. Numbers 29:5 Or purification offering; also elsewhere in this chapter
  12. Numbers 29:7 Or must fast
  13. Numbers 29:40 In Hebrew texts this verse (29:40) is numbered 30:1.

28 And the Lord spake unto Moses, saying,

Command the children of Israel, and say unto them, My offering, and my bread for my sacrifices made by fire, for a sweet savour unto me, shall ye observe to offer unto me in their due season.

And thou shalt say unto them, This is the offering made by fire which ye shall offer unto the Lord; two lambs of the first year without spot day by day, for a continual burnt offering.

The one lamb shalt thou offer in the morning, and the other lamb shalt thou offer at even;

And a tenth part of an ephah of flour for a meat offering, mingled with the fourth part of an hin of beaten oil.

It is a continual burnt offering, which was ordained in mount Sinai for a sweet savour, a sacrifice made by fire unto the Lord.

And the drink offering thereof shall be the fourth part of an hin for the one lamb: in the holy place shalt thou cause the strong wine to be poured unto the Lord for a drink offering.

And the other lamb shalt thou offer at even: as the meat offering of the morning, and as the drink offering thereof, thou shalt offer it, a sacrifice made by fire, of a sweet savour unto the Lord.

And on the sabbath day two lambs of the first year without spot, and two tenth deals of flour for a meat offering, mingled with oil, and the drink offering thereof:

10 This is the burnt offering of every sabbath, beside the continual burnt offering, and his drink offering.

11 And in the beginnings of your months ye shall offer a burnt offering unto the Lord; two young bullocks, and one ram, seven lambs of the first year without spot;

12 And three tenth deals of flour for a meat offering, mingled with oil, for one bullock; and two tenth deals of flour for a meat offering, mingled with oil, for one ram;

13 And a several tenth deal of flour mingled with oil for a meat offering unto one lamb; for a burnt offering of a sweet savour, a sacrifice made by fire unto the Lord.

14 And their drink offerings shall be half an hin of wine unto a bullock, and the third part of an hin unto a ram, and a fourth part of an hin unto a lamb: this is the burnt offering of every month throughout the months of the year.

15 And one kid of the goats for a sin offering unto the Lord shall be offered, beside the continual burnt offering, and his drink offering.

16 And in the fourteenth day of the first month is the passover of the Lord.

17 And in the fifteenth day of this month is the feast: seven days shall unleavened bread be eaten.

18 In the first day shall be an holy convocation; ye shall do no manner of servile work therein:

19 But ye shall offer a sacrifice made by fire for a burnt offering unto the Lord; two young bullocks, and one ram, and seven lambs of the first year: they shall be unto you without blemish:

20 And their meat offering shall be of flour mingled with oil: three tenth deals shall ye offer for a bullock, and two tenth deals for a ram;

21 A several tenth deal shalt thou offer for every lamb, throughout the seven lambs:

22 And one goat for a sin offering, to make an atonement for you.

23 Ye shall offer these beside the burnt offering in the morning, which is for a continual burnt offering.

24 After this manner ye shall offer daily, throughout the seven days, the meat of the sacrifice made by fire, of a sweet savour unto the Lord: it shall be offered beside the continual burnt offering, and his drink offering.

25 And on the seventh day ye shall have an holy convocation; ye shall do no servile work.

26 Also in the day of the firstfruits, when ye bring a new meat offering unto the Lord, after your weeks be out, ye shall have an holy convocation; ye shall do no servile work:

27 But ye shall offer the burnt offering for a sweet savour unto the Lord; two young bullocks, one ram, seven lambs of the first year;

28 And their meat offering of flour mingled with oil, three tenth deals unto one bullock, two tenth deals unto one ram,

29 A several tenth deal unto one lamb, throughout the seven lambs;

30 And one kid of the goats, to make an atonement for you.

31 Ye shall offer them beside the continual burnt offering, and his meat offering, (they shall be unto you without blemish) and their drink offerings.

29 And in the seventh month, on the first day of the month, ye shall have an holy convocation; ye shall do no servile work: it is a day of blowing the trumpets unto you.

And ye shall offer a burnt offering for a sweet savour unto the Lord; one young bullock, one ram, and seven lambs of the first year without blemish:

And their meat offering shall be of flour mingled with oil, three tenth deals for a bullock, and two tenth deals for a ram,

And one tenth deal for one lamb, throughout the seven lambs:

And one kid of the goats for a sin offering, to make an atonement for you:

Beside the burnt offering of the month, and his meat offering, and the daily burnt offering, and his meat offering, and their drink offerings, according unto their manner, for a sweet savour, a sacrifice made by fire unto the Lord.

And ye shall have on the tenth day of this seventh month an holy convocation; and ye shall afflict your souls: ye shall not do any work therein:

But ye shall offer a burnt offering unto the Lord for a sweet savour; one young bullock, one ram, and seven lambs of the first year; they shall be unto you without blemish:

And their meat offering shall be of flour mingled with oil, three tenth deals to a bullock, and two tenth deals to one ram,

10 A several tenth deal for one lamb, throughout the seven lambs:

11 One kid of the goats for a sin offering; beside the sin offering of atonement, and the continual burnt offering, and the meat offering of it, and their drink offerings.

12 And on the fifteenth day of the seventh month ye shall have an holy convocation; ye shall do no servile work, and ye shall keep a feast unto the Lord seven days:

13 And ye shall offer a burnt offering, a sacrifice made by fire, of a sweet savour unto the Lord; thirteen young bullocks, two rams, and fourteen lambs of the first year; they shall be without blemish:

14 And their meat offering shall be of flour mingled with oil, three tenth deals unto every bullock of the thirteen bullocks, two tenth deals to each ram of the two rams,

15 And a several tenth deal to each lamb of the fourteen lambs:

16 And one kid of the goats for a sin offering; beside the continual burnt offering, his meat offering, and his drink offering.

17 And on the second day ye shall offer twelve young bullocks, two rams, fourteen lambs of the first year without spot:

18 And their meat offering and their drink offerings for the bullocks, for the rams, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

19 And one kid of the goats for a sin offering; beside the continual burnt offering, and the meat offering thereof, and their drink offerings.

20 And on the third day eleven bullocks, two rams, fourteen lambs of the first year without blemish;

21 And their meat offering and their drink offerings for the bullocks, for the rams, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

22 And one goat for a sin offering; beside the continual burnt offering, and his meat offering, and his drink offering.

23 And on the fourth day ten bullocks, two rams, and fourteen lambs of the first year without blemish:

24 Their meat offering and their drink offerings for the bullocks, for the rams, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

25 And one kid of the goats for a sin offering; beside the continual burnt offering, his meat offering, and his drink offering.

26 And on the fifth day nine bullocks, two rams, and fourteen lambs of the first year without spot:

27 And their meat offering and their drink offerings for the bullocks, for the rams, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

28 And one goat for a sin offering; beside the continual burnt offering, and his meat offering, and his drink offering.

29 And on the sixth day eight bullocks, two rams, and fourteen lambs of the first year without blemish:

30 And their meat offering and their drink offerings for the bullocks, for the rams, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

31 And one goat for a sin offering; beside the continual burnt offering, his meat offering, and his drink offering.

32 And on the seventh day seven bullocks, two rams, and fourteen lambs of the first year without blemish:

33 And their meat offering and their drink offerings for the bullocks, for the rams, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

34 And one goat for a sin offering; beside the continual burnt offering, his meat offering, and his drink offering.

35 On the eighth day ye shall have a solemn assembly: ye shall do no servile work therein:

36 But ye shall offer a burnt offering, a sacrifice made by fire, of a sweet savour unto the Lord: one bullock, one ram, seven lambs of the first year without blemish:

37 Their meat offering and their drink offerings for the bullock, for the ram, and for the lambs, shall be according to their number, after the manner:

38 And one goat for a sin offering; beside the continual burnt offering, and his meat offering, and his drink offering.

39 These things ye shall do unto the Lord in your set feasts, beside your vows, and your freewill offerings, for your burnt offerings, and for your meat offerings, and for your drink offerings, and for your peace offerings.

40 And Moses told the children of Israel according to all that the Lord commanded Moses.