Add parallel Print Page Options

Okùn ìwọ̀n ti Jerusalẹmu

Mó si tún gbé ojú mi, sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀. Mo sí wí pé, “Níbo ni ìwọ ń lọ?”

O sí wí fún mí pé, “Láti wọn Jerusalẹmu, láti rí iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀.”

Sì kíyèsi i, angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀. Ó si wí fún un pé, “Sáré, sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin yìí wí pé, ‘A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti kò ní odi, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ọ̀sìn inú rẹ̀. Olúwa wí pé, Èmí ó sì jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó sì jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’

“Wá! Wá! Sá kúrò ni ilẹ̀ àríwá, ni Olúwa wí; nítorí pé bí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ọ̀run ni mo tú yín káàkiri,” ni Olúwa wí.

“Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ tí ó ń bà ọmọbìnrin Babeli gbé.” Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ń kó yin: nítorí ẹni tí ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀. Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi sí orí wọn, wọn yóò sì jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.

10 “Kọrin kí o sì yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni: Nítorí èmi ń bọ̀ àti pé èmi yóò sì gbé àárín rẹ,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. 11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ní ọjọ́ náà, wọn yóò sì di ènìyàn mi: èmi yóò sì gbé àárín rẹ, ìwọ yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi sí ọ. 12 Olúwa yóò sì jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò sì tún yan Jerusalẹmu. 13 (A)Ẹ̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a jí i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ wá.”

A Man With a Measuring Line

[a]Then I looked up, and there before me was a man with a measuring line in his hand. I asked, “Where are you going?”

He answered me, “To measure Jerusalem, to find out how wide and how long it is.”(A)

While the angel who was speaking to me was leaving, another angel came to meet him and said to him: “Run, tell that young man, ‘Jerusalem will be a city without walls(B) because of the great number(C) of people and animals in it.(D) And I myself will be a wall(E) of fire(F) around it,’ declares the Lord, ‘and I will be its glory(G) within.’(H)

“Come! Come! Flee from the land of the north,” declares the Lord, “for I have scattered(I) you to the four winds of heaven,”(J) declares the Lord.(K)

“Come, Zion! Escape,(L) you who live in Daughter Babylon!”(M) For this is what the Lord Almighty says: “After the Glorious One has sent me against the nations that have plundered you—for whoever touches you touches the apple of his eye(N) I will surely raise my hand against them so that their slaves will plunder them.[b](O) Then you will know that the Lord Almighty has sent me.(P)

10 “Shout(Q) and be glad, Daughter Zion.(R) For I am coming,(S) and I will live among you,”(T) declares the Lord.(U) 11 “Many nations will be joined with the Lord in that day and will become my people.(V) I will live among you and you will know that the Lord Almighty has sent me to you.(W) 12 The Lord will inherit(X) Judah(Y) as his portion in the holy land and will again choose(Z) Jerusalem. 13 Be still(AA) before the Lord, all mankind, because he has roused himself from his holy dwelling.(AB)

Footnotes

  1. Zechariah 2:1 In Hebrew texts 2:1-13 is numbered 2:5-17.
  2. Zechariah 2:9 Or says after … eye: “I … plunder them.”