Add parallel Print Page Options

Saamu ti Asafu.

82 Ọlọ́run ń ṣàkóso nínú ìpéjọpọ̀ ńlá,
    ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn “ọlọ́run òrìṣà”.

“Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa gbèjà àwọn aláìṣòdodo
    kí ó sì ṣe ojú ìṣáájú sí àwọn ènìyàn búburú?
Gbèjà àwọn aláìlágbára àti aláìní baba;
    ṣe ìtọ́jú ẹ̀tọ́ àwọn aláìní àti ẹni ìnilára.
Gba àwọn aláìlágbára àti aláìní;
    gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú.

“Wọn kò mọ̀ ohun kankan,
    wọn kò lóye ohun kankan.
Wọn ń rìn kiri nínú òkùnkùn;
    à si mí gbogbo ìpìlẹ̀ ayé.

(A)“Mo wí pé, ‘Ẹyin ní “Ọlọ́run òrìṣà”;
    ẹ̀yin ní gbogbo ọmọ Ọ̀gá-ògo jùlọ.’
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ó kú bí ènìyàn lásán;
    ẹ̀yin ó ṣubú bí ọ̀kan nínú ọmọ-aládé.”

Dìde, Ọlọ́run, ṣe ìdájọ́ ayé,
    nítorí gbogbo orílẹ̀-èdè ni ìní rẹ.

Psalm 82

A psalm of Asaph.

God presides in the great assembly;
    he renders judgment(A) among the “gods”:(B)

“How long will you[a] defend the unjust
    and show partiality(C) to the wicked?[b](D)
Defend the weak and the fatherless;(E)
    uphold the cause of the poor(F) and the oppressed.
Rescue the weak and the needy;
    deliver them from the hand of the wicked.

“The ‘gods’ know nothing, they understand nothing.(G)
    They walk about in darkness;(H)
    all the foundations(I) of the earth are shaken.

“I said, ‘You are “gods”;(J)
    you are all sons of the Most High.’
But you will die(K) like mere mortals;
    you will fall like every other ruler.”

Rise up,(L) O God, judge(M) the earth,
    for all the nations are your inheritance.(N)

Footnotes

  1. Psalm 82:2 The Hebrew is plural.
  2. Psalm 82:2 The Hebrew has Selah (a word of uncertain meaning) here.