Add parallel Print Page Options

(A)Èmi yóò sì kéde ìpinnu Olúwa:

Ó sọ fún mi pé, “Ìwọ ni ọmọ mi;
    lónìí, èmi ti di baba rẹ.

Read full chapter

I will proclaim the Lord’s decree:

He said to me, “You are my son;(A)
    today I have become your father.(B)

Read full chapter

Ìránṣẹ́ Olúwa náà

42 (A)“Ìránṣẹ́ mi nìyìí, ẹni tí mo gbéró,
    àyànfẹ́ mi nínú ẹni tí mo láyọ̀;
Èmi yóò fi Ẹ̀mí mi sínú rẹ̀
    òun yóò sì mú ìdájọ́ wá sórí àwọn orílẹ̀-èdè.

Read full chapter

The Servant of the Lord

42 “Here is my servant,(A) whom I uphold,
    my chosen one(B) in whom I delight;(C)
I will put my Spirit(D) on him,
    and he will bring justice(E) to the nations.(F)

Read full chapter

35 (A)Ohùn kan sì ti inú ìkùùkuu wá wí pé, “Èyí yìí ni àyànfẹ́ ọmọ mi: ẹ máa gbọ́ tirẹ̀.”

Read full chapter

35 A voice came from the cloud, saying, “This is my Son, whom I have chosen;(A) listen to him.”(B)

Read full chapter

38 Àní Jesu ti Nasareti, gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti da Ẹ̀mí Mímọ́ àti agbára le lórí; ẹni tí ó ń kiri ṣe oore, ó ń ṣe ìmúláradá gbogbo àwọn tí èṣù sì ń pọ́n lójú; nítorí Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀.

Read full chapter

38 how God anointed(A) Jesus of Nazareth with the Holy Spirit and power, and how he went around doing good and healing(B) all who were under the power of the devil, because God was with him.(C)

Read full chapter

17 (A)Nítorí tí Ó gba ọlá àti ògo láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, nígbà tí irú ohùn yìí fọ̀ sí i láti inú ògo ńlá náà wá pé, “Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹni tí inú mi dùn sí gidigidi.”

Read full chapter

17 He received honor and glory from God the Father when the voice came to him from the Majestic Glory, saying, “This is my Son, whom I love; with him I am well pleased.”[a](A)

Read full chapter

Footnotes

  1. 2 Peter 1:17 Matt. 17:5; Mark 9:7; Luke 9:35