Add parallel Print Page Options

Bíbá ẹ̀ṣẹ̀ wọ ìjàkadì

(A)Ǹjẹ́ àwa o ha ti wí, nígbà náà? Òfin ha ń ṣe ẹ̀ṣẹ̀ bí? Kí a má rí i! Ṣùgbọ́n èmi kì bá tí mọ ohun tí ẹ̀ṣẹ̀ jẹ́, bí kò ṣe nípa òfin. Èmi kì bá tí mọ ojúkòkòrò, bí kò ṣe bí òfin ti wí pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò.” (B)Ṣùgbọ́n ẹ̀ṣẹ̀ sì ti ipa òfin rí ààyè ṣiṣẹ́ onírúurú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ nínú mi. Nítorí láìsí òfin, ẹ̀ṣẹ̀ jẹ́ ikú.

Read full chapter

The Law and Sin

What shall we say, then?(A) Is the law sinful? Certainly not!(B) Nevertheless, I would not have known what sin was had it not been for the law.(C) For I would not have known what coveting really was if the law had not said, “You shall not covet.”[a](D) But sin, seizing the opportunity afforded by the commandment,(E) produced in me every kind of coveting. For apart from the law, sin was dead.(F)

Read full chapter

Footnotes

  1. Romans 7:7 Exodus 20:17; Deut. 5:21

19 (A)Ǹjẹ́ kí ha ni òfin? A fi kún un nítorí ìrékọjá títí irú-ọmọ tí a ti ṣe ìlérí fún yóò fi dé; a sì tipasẹ̀ àwọn angẹli ṣe ìlànà rẹ̀ láti ọwọ́ alárinà kan wá.

Read full chapter

19 Why, then, was the law given at all? It was added because of transgressions(A) until the Seed(B) to whom the promise referred had come. The law was given through angels(C) and entrusted to a mediator.(D)

Read full chapter

14 Oore-ọ̀fẹ́ Olúwa wa sì pọ̀ rékọjá pẹ̀lú ìgbàgbọ́ àti ìfẹ́, tí ń bẹ nínú Kristi Jesu.

Read full chapter

14 The grace of our Lord was poured out on me abundantly,(A) along with the faith and love that are in Christ Jesus.(B)

Read full chapter