Add parallel Print Page Options

Ààlà ti Kenaani

34 Olúwa sọ fún Mose pé, “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí o sì sọ fún wọn pé: ‘Tí ẹ bá wọ Kenaani, ilẹ̀ tí a ó fi fún yín, gẹ́gẹ́ bí ogún yín yóò ní ààlà wọn yí:

(A)“ ‘Ìhà gúúsù yín yóò bọ́ sí ara aginjù Sini lẹ́bàá Edomu, àti ìlà-oòrùn, ààlà ìhà gúúsù yóò bẹ̀rẹ̀ láti òpin Òkun Iyọ̀, kọjá lọ sí gúúsù Akrabbimu, tẹ̀síwájú lọ si Sini: kó bọ́ si gúúsù Kadeṣi-Barnea, kí o sì dé Hasari-Addari, kí o sì kọjá sí Asmoni. Kí òpin ilẹ̀ rẹ̀ kí ó sì yíká láti Asmoni lọ dé odò Ejibiti, Òkun ni yóò sì jẹ òpin rẹ.

Ìhà ìwọ̀-oòrùn yín yóò jẹ́ òpin lórí Òkun ńlá. Èyí yóò jẹ́ ààlà yín lórí ìhà ìwọ̀-oòrùn.

Fún ààlà ìhà àríwá, fa ìlà láti Òkun ńlá lọ sí orí òkè Hori Àti láti orí òkè Hori sí Lebo-Hamati. Nígbà náà ààlà náà yóò lọ sí Ṣedadi, Tẹ̀síwájú lọ sí Sifroni, kí o sì fò pín si ní Hasari-Enani, Èyí yóò jẹ́ ààlà tìrẹ ní ìhà àríwá.

10 Kí ẹ sì sàmì sí ilẹ̀ tiyín ní ìhà ìlà-oòrùn láti Hasari-Enani lọ dé Ṣefamu. 11 Ààlà náà yóò ti Ṣefamu sọ̀kalẹ̀ wá lọ sí Ribla ní ìhà ìlà-oòrùn Aini, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ dé ìhà Òkun Kinnereti ní ìhà ìlà-oòrùn. 12 Nígbà náà, ààlà náà yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sí apá Jordani, yóò sì dópin nínú Òkun.

“ ‘Èyí yóò jẹ́ ilẹ̀ yín, pẹ̀lú ààlà tirẹ̀ ní gbogbo ọ̀nà.’ ”

13 (B)Mose pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé: “Yan ilẹ̀ yìí pẹ̀lú kèké gẹ́gẹ́ bí ìní ogún: Olúwa ti pàṣẹ láti fi fún ẹ̀yà mẹ́sàn-án, àti ààbọ̀. 14 Nítorí ará ilẹ̀ ẹ̀yà ti Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ẹ̀yà ààbọ̀ ti Manase ti gba ogún tiwọn. 15 Ẹ̀yà méjèèjì àti ààbọ̀ yìí ti gba ogún tiwọn ní ìhà ìhín Jordani létí i Jeriko, ní ìhà ìlà-oòrùn, ní ìdojúkọ Jordani.”

16 Olúwa sọ fún Mose pé, 17 “Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà tí yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ogún: Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni. 18 Kí o sì yan olórí kan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti pín ilẹ̀ náà.

19 “Èyí ni orúkọ wọn:

“Kalebu ọmọ Jefunne, láti ẹ̀yà Juda;

20 Ṣemueli ọmọ Ammihudu, láti ẹ̀yà Simeoni;

21 Elidadi ọmọ Kisloni, láti ẹ̀yà Benjamini;

22 Bukki ọmọ Jogli, láti ẹ̀yà olórí àwọn ọmọ Dani;

23 Hannieli ọmọ Efodu, láti ẹ̀yà Manase, olórí àwọn ọmọ Josẹfu,

24 Kemueli ọmọ Ṣiftani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ, Efraimu, ọmọ Josẹfu;

25 Elisafani ọmọ Parnaki, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Sebuluni;

26 Paltieli ọmọ Assani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Isakari;

27 Ahihudu ọmọ Ṣelomi, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Aṣeri;

28 Pedaheli ọmọ Ammihudu, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Naftali.”

29 Èyí ni àwọn ẹni tí Olúwa yàn láti pín ogún náà fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani.

34 And the Lord spake unto Moses, saying,

Command the children of Israel, and say unto them, When ye come into the land of Canaan; (this is the land that shall fall unto you for an inheritance, even the land of Canaan with the coasts thereof:)

Then your south quarter shall be from the wilderness of Zin along by the coast of Edom, and your south border shall be the outmost coast of the salt sea eastward:

And your border shall turn from the south to the ascent of Akrabbim, and pass on to Zin: and the going forth thereof shall be from the south to Kadeshbarnea, and shall go on to Hazaraddar, and pass on to Azmon:

And the border shall fetch a compass from Azmon unto the river of Egypt, and the goings out of it shall be at the sea.

And as for the western border, ye shall even have the great sea for a border: this shall be your west border.

And this shall be your north border: from the great sea ye shall point out for you mount Hor:

From mount Hor ye shall point out your border unto the entrance of Hamath; and the goings forth of the border shall be to Zedad:

And the border shall go on to Ziphron, and the goings out of it shall be at Hazarenan: this shall be your north border.

10 And ye shall point out your east border from Hazarenan to Shepham:

11 And the coast shall go down from Shepham to Riblah, on the east side of Ain; and the border shall descend, and shall reach unto the side of the sea of Chinnereth eastward:

12 And the border shall go down to Jordan, and the goings out of it shall be at the salt sea: this shall be your land with the coasts thereof round about.

13 And Moses commanded the children of Israel, saying, This is the land which ye shall inherit by lot, which the Lord commanded to give unto the nine tribes, and to the half tribe:

14 For the tribe of the children of Reuben according to the house of their fathers, and the tribe of the children of Gad according to the house of their fathers, have received their inheritance; and half the tribe of Manasseh have received their inheritance:

15 The two tribes and the half tribe have received their inheritance on this side Jordan near Jericho eastward, toward the sunrising.

16 And the Lord spake unto Moses, saying,

17 These are the names of the men which shall divide the land unto you: Eleazar the priest, and Joshua the son of Nun.

18 And ye shall take one prince of every tribe, to divide the land by inheritance.

19 And the names of the men are these: Of the tribe of Judah, Caleb the son of Jephunneh.

20 And of the tribe of the children of Simeon, Shemuel the son of Ammihud.

21 Of the tribe of Benjamin, Elidad the son of Chislon.

22 And the prince of the tribe of the children of Dan, Bukki the son of Jogli.

23 The prince of the children of Joseph, for the tribe of the children of Manasseh, Hanniel the son of Ephod.

24 And the prince of the tribe of the children of Ephraim, Kemuel the son of Shiphtan.

25 And the prince of the tribe of the children of Zebulun, Elizaphan the son of Parnach.

26 And the prince of the tribe of the children of Issachar, Paltiel the son of Azzan.

27 And the prince of the tribe of the children of Asher, Ahihud the son of Shelomi.

28 And the prince of the tribe of the children of Naphtali, Pedahel the son of Ammihud.

29 These are they whom the Lord commanded to divide the inheritance unto the children of Israel in the land of Canaan.

Fronteras de la tierra prometida

34 El Señor se dirigió a Moisés y le dijo:

— Da estas normas a los israelitas: cuando entren en el país de Canaán, estas serán las fronteras de la tierra que les tocará como heredad:

La frontera sur se extenderá desde el desierto de Sin hasta el límite con Edom, arrancando del extremo sur del Mar Muerto hacia el oriente. Luego la frontera torcerá hacia el sur hasta la cuesta de Acrabín y continuará hasta Sin; se extenderá hasta el sur de Cadés Barnea, pasando por Jasar Adar y continuando hasta Asmón. Desde Asmón la frontera torcerá hacia el torrente de Egipto y terminará en el mar.

Por frontera oeste tendrán la costa del mar Grande; este te servirá de frontera occidental.

La frontera norte será esta: desde el mar Grande trazarán una línea hasta el monte Hor; y desde el monte Hor trazarán otra línea que, pasando por Lebó Jamat, se prolongue hasta Zedad. La frontera seguirá hasta Zifrón y terminará en Jasar Enán. Esta será la frontera norte.

10 Para la frontera este trazarán una línea desde Jasar Enán hasta Sefán. 11 Desde Sefán la frontera bajará a Ribla, al lado este de Ain; desde allí la frontera descenderá y llegará hasta la ribera oriental del lago de Kinéret. 12 La frontera descenderá luego a lo largo del Jordán y terminará en el Mar Muerto. Esta será su tierra con sus respectivas fronteras circundantes.

13 Moisés dio entonces a los israelitas las siguientes instrucciones:

— Esta es la tierra que recibirán por sorteo como porción hereditaria y que el Señor ha mandado que se dé a las nueve tribus y media. 14 Porque las tribus de Rubén y de Gad, junto con la media tribu de Manasés, ya han recibido su porción, según sus respectivas casas patriarcales. 15 Esas dos tribus y media recibieron ya su porción a este lado del Jordán, a la altura de Jericó, al oriente.

Los encargados del reparto

16 El Señor se dirigió a Moisés y le dijo:

17 — Estos son los nombres de quienes harán el reparto de la tierra: Eleazar, el sacerdote, y Josué, hijo de Nun, 18 a quienes acompañarán en el reparto de la tierra un jefe de cada tribu. 19 Estos son sus respectivos nombres: De la tribu de Judá, Caleb, hijo de Jefuné. 20 De la tribu de los descendientes de Simeón, Semuel, hijo de Amihud. 21 De la tribu de Benjamín, Elidad, hijo de Quislón. 22 De la tribu de los descendientes de Dan, el jefe Buquí, hijo de Joglí. 23 Por parte de los hijos de José: de la tribu de los descendientes de Manasés, el jefe Janiel, hijo de Efod; 24 y de la tribu de los descendientes de Efraín, el jefe Kemuel, hijo de Siftán. 25 De la tribu de los descendientes de Zabulón, el jefe Elisafán, hijo de Parnac. 26 De la tribu de los descendientes de Isacar, el jefe Paltiel, hijo de Azán. 27 De la tribu de los descendientes de Aser, el jefe Ajihud, hijo de Selomí. 28 Y de la tribu de los descendientes de Neftalí, el jefe Pedael, hijo de Amihud.

29 A estos designó el Señor para que repartieran entre los israelitas el país de Canaán.

Boundaries of Canaan

34 The Lord said to Moses, “Command the Israelites and say to them: ‘When you enter Canaan,(A) the land that will be allotted to you as an inheritance(B) is to have these boundaries:(C)

“‘Your southern side will include some of the Desert of Zin(D) along the border of Edom. Your southern boundary will start in the east from the southern end of the Dead Sea,(E) cross south of Scorpion Pass,(F) continue on to Zin and go south of Kadesh Barnea.(G) Then it will go to Hazar Addar and over to Azmon,(H) where it will turn, join the Wadi of Egypt(I) and end at the Mediterranean Sea.

“‘Your western boundary will be the coast of the Mediterranean Sea.(J) This will be your boundary on the west.(K)

“‘For your northern boundary,(L) run a line from the Mediterranean Sea to Mount Hor(M) and from Mount Hor to Lebo Hamath.(N) Then the boundary will go to Zedad, continue to Ziphron and end at Hazar Enan. This will be your boundary on the north.

10 “‘For your eastern boundary,(O) run a line from Hazar Enan to Shepham. 11 The boundary will go down from Shepham to Riblah(P) on the east side of Ain(Q) and continue along the slopes east of the Sea of Galilee.[a](R) 12 Then the boundary will go down along the Jordan and end at the Dead Sea.

“‘This will be your land, with its boundaries on every side.’”

13 Moses commanded the Israelites: “Assign this land by lot(S) as an inheritance.(T) The Lord has ordered that it be given to the nine and a half tribes, 14 because the families of the tribe of Reuben, the tribe of Gad and the half-tribe of Manasseh have received their inheritance.(U) 15 These two and a half tribes have received their inheritance east of the Jordan across from Jericho, toward the sunrise.”

16 The Lord said to Moses, 17 “These are the names of the men who are to assign the land for you as an inheritance: Eleazar the priest and Joshua(V) son of Nun. 18 And appoint one leader from each tribe to help(W) assign the land.(X) 19 These are their names:(Y)

Caleb(Z) son of Jephunneh,

from the tribe of Judah;(AA)

20 Shemuel son of Ammihud,

from the tribe of Simeon;(AB)

21 Elidad son of Kislon,

from the tribe of Benjamin;(AC)

22 Bukki son of Jogli,

the leader from the tribe of Dan;

23 Hanniel son of Ephod,

the leader from the tribe of Manasseh(AD) son of Joseph;

24 Kemuel son of Shiphtan,

the leader from the tribe of Ephraim(AE) son of Joseph;

25 Elizaphan son of Parnak,

the leader from the tribe of Zebulun;(AF)

26 Paltiel son of Azzan,

the leader from the tribe of Issachar;

27 Ahihud son of Shelomi,

the leader from the tribe of Asher;(AG)

28 Pedahel son of Ammihud,

the leader from the tribe of Naphtali.”

29 These are the men the Lord commanded to assign the inheritance to the Israelites in the land of Canaan.(AH)

Footnotes

  1. Numbers 34:11 Hebrew Kinnereth