Add parallel Print Page Options

11 Mo sì wí fún yín, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni yóò ti ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn wá, wọ́n á sì bá Abrahamu àti Isaaki àti Jakọbu jẹun ní ìjọba ọ̀run. 12 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìjọba ni a ó sọ sínú òkùnkùn lóde, níbẹ̀ ni ẹkún àti ìpayínkeke yóò gbé wà.”

Read full chapter

11 I say to you that many will come from the east and the west,(A) and will take their places at the feast with Abraham, Isaac and Jacob in the kingdom of heaven.(B) 12 But the subjects of the kingdom(C) will be thrown outside, into the darkness, where there will be weeping and gnashing of teeth.”(D)

Read full chapter