Add parallel Print Page Options

22 (A)Nígbà tí wọ́n sì ti wà ní Galili, Jesu sọ fún wọn pé, “Láìpẹ́ yìí a ó fi Ọmọ ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́. 23 Wọn yóò sì pa á, ní ọjọ́ kẹta lẹ́yìn èyí, yóò sì jí dìde sí ìyè.” Ọkàn àwọn Ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì kún fún ìbànújẹ́ gidigidi.

Read full chapter

Jesus Predicts His Death a Second Time

22 When they came together in Galilee, he said to them, “The Son of Man(A) is going to be delivered into the hands of men. 23 They will kill him,(B) and on the third day(C) he will be raised to life.”(D) And the disciples were filled with grief.

Read full chapter

30 (A)Wọ́n sì kúrò níbẹ̀, wọ́n gba Galili kọjá. Níbẹ̀ ni Jesu ti gbìyànjú láti yẹra kí ó bá à lè wà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, kí ó lè ráàyè kọ́ wọn lẹ́kọ̀ọ́ sí i. 31 (B)Nítorí ó kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sì wí fun wọn pe, “A ó fi Ọmọ ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́, wọn ó sì pa á, lẹ́yìn ìgbà tí a bá sì pa á tan yóò jíǹde ní ọjọ́ kẹta.” 32 (C)Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yé wọn, ẹ̀rù sì bà wọ́n láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ìtumọ̀ ohun tí ó sọ náà.

Read full chapter

Jesus Predicts His Death a Second Time(A)

30 They left that place and passed through Galilee. Jesus did not want anyone to know where they were, 31 because he was teaching his disciples. He said to them, “The Son of Man(B) is going to be delivered into the hands of men. They will kill him,(C) and after three days(D) he will rise.”(E) 32 But they did not understand what he meant(F) and were afraid to ask him about it.

Read full chapter

22 (A)Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn yóò jìyà ohun púpọ̀, a ó sì kọ̀ ọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn alàgbà, olórí àlùfáà àti láti ọ̀dọ̀ àwọn akọ̀wé, a ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta a ó sì jí i dìde.”

Read full chapter

22 And he said, “The Son of Man(A) must suffer many things(B) and be rejected by the elders, the chief priests and the teachers of the law,(C) and he must be killed(D) and on the third day(E) be raised to life.”(F)

Read full chapter

Jesu tún sọ nípa ikú rẹ̀

31 (A)Nígbà náà ni ó pe àwọn méjìlá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí fún wọn pé, “Sá wò ó, àwa ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu, a ó sì mú ohun gbogbo ṣẹ, tí a ti kọ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, nítorí Ọmọ Ènìyàn. 32 Nítorí tí a ó fi lé àwọn aláìkọlà lọ́wọ́, a ó fi ṣe ẹlẹ́yà, a ó sì fi ṣe ẹ̀sín, a ó sì tutọ́ sí i lára. 33 Wọn ó sì nà án, wọn ó sì pa á: ní ọjọ́ kẹta yóò sì jíǹde.”

34 Ọ̀kan nínú nǹkan wọ̀nyí kò sì yé wọn: ọ̀rọ̀ yìí sì pamọ́ fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì mọ ohun tí a wí.

Read full chapter

Jesus Predicts His Death a Third Time(A)

31 Jesus took the Twelve aside and told them, “We are going up to Jerusalem,(B) and everything that is written by the prophets(C) about the Son of Man(D) will be fulfilled. 32 He will be delivered over to the Gentiles.(E) They will mock him, insult him and spit on him; 33 they will flog him(F) and kill him.(G) On the third day(H) he will rise again.”(I)

34 The disciples did not understand any of this. Its meaning was hidden from them, and they did not know what he was talking about.(J)

Read full chapter

25 (A)Ṣùgbọ́n kò lè ṣàìmá kọ́ jìyà ohun púpọ̀, kí a sì kọ̀ ọ́ lọ́dọ̀ ìran yìí.

Read full chapter

25 But first he must suffer many things(A) and be rejected(B) by this generation.(C)

Read full chapter