Add parallel Print Page Options

Nígbà náà, Jesu wí fún wọn pé, “A máa ń bu ọlá fún wòlíì níbi gbogbo àfi ní ìlú ara rẹ̀ àti láàrín àwọn ìdílé àti àwọn ẹbí òun pàápàá.”

Read full chapter

Jesus said to them, “A prophet is not without honor except in his own town, among his relatives and in his own home.”(A)

Read full chapter

57 Inú bí wọn sí i.

Ṣùgbọ́n Jesu wí fún wọn pé, “Wòlíì a máa lọ́lá ní ibòmíràn, àfi ní ilé ara rẹ̀ àti ní ìlú ara rẹ̀ nìkan ni wòlíì kò ti lọ́lá.”

Read full chapter

57 And they took offense(A) at him.

But Jesus said to them, “A prophet is not without honor except in his own town and in his own home.”(B)

Read full chapter