Add parallel Print Page Options

Rírán Mesiah náà

(A)“Wò ó, Èmi yóò ran ìránṣẹ́ mi, yóò tún ọ̀nà ṣe ṣáájú mi. Nígbà náà ni Olúwa, tí ẹ̀yin ń wa, yóò dé ni òjijì sí tẹmpili rẹ̀; àní oníṣẹ́ májẹ̀mú náà, tí inú yín dùn sí, yóò dé,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.

Read full chapter

“I will send my messenger,(A) who will prepare the way before me.(B) Then suddenly the Lord(C) you are seeking will come to his temple; the messenger of the covenant,(D) whom you desire,(E) will come,” says the Lord Almighty.

Read full chapter

10 Èyí ni ẹni tí a ti kọ̀wé rẹ̀ pé:

“ ‘Èmi yóò rán ìránṣẹ́ mi síwájú rẹ,
    ẹni tí yóò tún ọ̀nà rẹ ṣe níwájú rẹ.’

Read full chapter

10 This is the one about whom it is written:

“‘I will send my messenger ahead of you,(A)
    who will prepare your way before you.’[a](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Matthew 11:10 Mal. 3:1

27 (A)Èyí yìí ni ẹni tí a ti kọ̀wé nítorí rẹ̀ pé:

“ ‘Wò ó, èmi yóò rán oníṣẹ́ mi síwájú rẹ;
    ẹni tí yóò tún ọ̀nà rẹ ṣe níwájú rẹ.’

Read full chapter

27 This is the one about whom it is written:

“‘I will send my messenger ahead of you,
    who will prepare your way before you.’[a](A)

Read full chapter

Footnotes

  1. Luke 7:27 Mal. 3:1