Add parallel Print Page Options

39 (A)Ẹ wo ọwọ́ mi àti ẹsẹ̀ mi, pé èmi tìkára mi ni! Ẹ dì mímú kí ẹ wò ó nítorí tí iwin kò ní ẹran àti egungun lára, bí ẹ̀yin ti rí tí èmi ní.”

Read full chapter

39 Look at my hands and my feet. It is I myself! Touch me and see;(A) a ghost does not have flesh and bones, as you see I have.”

Read full chapter

Ọ̀rọ̀ di ẹran-ara

(A)Ní àtètèkọ́ṣe ni Ọ̀rọ̀ wà, Ọ̀rọ̀ sì wà pẹ̀lú Ọlọ́run, Ọlọ́run sì ni Ọ̀rọ̀ náà.

Read full chapter

The Word Became Flesh

In the beginning was the Word,(A) and the Word was with God,(B) and the Word was God.(C)

Read full chapter

14 (A)Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá mu nínú omi tí èmi ó fi fún un, òǹgbẹ kì yóò gbẹ ẹ́ mọ́ láé; ṣùgbọ́n omi tí èmi ó fi fún un yóò di kànga omi nínú rẹ̀, tí yóò máa sun si ìyè àìnípẹ̀kun.”

Read full chapter

14 but whoever drinks the water I give them will never thirst.(A) Indeed, the water I give them will become in them a spring of water(B) welling up to eternal life.”(C)

Read full chapter

27 (A)Ẹ̀yin pẹ̀lú yóò sì jẹ́rìí mi, nítorí tí ẹ̀yin ti wà pẹ̀lú mi láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ wá.

Read full chapter

27 And you also must testify,(A) for you have been with me from the beginning.(B)

Read full chapter

20 Nígbà tí ó sì ti wí bẹ́ẹ̀ tán, ó fi ọwọ́ àti ìhà rẹ̀ hàn wọ́n. Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yọ̀, nígbà tí wọ́n rí Olúwa.

Read full chapter

20 After he said this, he showed them his hands and side.(A) The disciples were overjoyed(B) when they saw the Lord.

Read full chapter

25 Nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ìyókù wí fún un pé, “Àwa ti rí Olúwa!”

Ṣùgbọ́n ó wí fún un pé, “Bí kò ṣe pé mo bá rí àpá ìṣó ni ọwọ́ rẹ̀ kí èmi sì fi ìka mi sí àpá ìṣó náà, kí èmi sì fi ọwọ́ mi sí ìhà rẹ̀, èmi kì yóò gbàgbọ́!”

Read full chapter

25 So the other disciples told him, “We have seen the Lord!”

But he said to them, “Unless I see the nail marks in his hands and put my finger where the nails were, and put my hand into his side,(A) I will not believe.”(B)

Read full chapter

20 Àwa kò lè ṣàìmá sọ ohun tí àwa ń rí, tí a sì ti gbọ́.”

Read full chapter

20 As for us, we cannot help speaking(A) about what we have seen and heard.”(B)

Read full chapter

13 (A)Èmi ń kọ̀wé sí yín, ẹ̀yin baba,
    nítorí tí ẹ̀yin tí mọ ẹni tí ó wà ní àtètèkọ́ṣe,
Èmi ń kọ̀wé sí yín, ẹ̀yin ọ̀dọ́mọkùnrin,
    nítorí tí ẹ̀yin ti ṣẹ́gun ẹni ibi náà.

Read full chapter

13 I am writing to you, fathers,
    because you know him who is from the beginning.(A)
I am writing to you, young men,
    because you have overcome(B) the evil one.(C)

Read full chapter