Add parallel Print Page Options

19 (A)Ó sì mú àkàrà, nígbà tí ó sì ti dúpẹ́ ó bù ú, ó sì fi fún wọn, ó wí pé, “Èyí ni ara mí tí a fi fún yín: ẹ máa ṣe èyí ní ìrántí mi.”

Read full chapter

19 And he took bread, gave thanks and broke it,(A) and gave it to them, saying, “This is my body given for you; do this in remembrance of me.”

Read full chapter

30 (A)Ó sì ṣe, bí ó ti bá wọn jókòó ti oúnjẹ, ó mú àkàrà, ó súre sí i, ó sì bù ú, ó sì fi fún wọn. 31 Ojú wọn sì là, wọ́n sì mọ̀ ọ́n; ó sì nù mọ́ wọn ní ojú

Read full chapter

30 When he was at the table with them, he took bread, gave thanks, broke it(A) and began to give it to them. 31 Then their eyes were opened and they recognized him,(B) and he disappeared from their sight.

Read full chapter

Ìsọ̀kan àwọn ará tí o gbàgbọ́

42 Wọ́n sì dúró ṣinṣin nínú ẹ̀kọ́ àwọn aposteli, àti ní ìdàpọ̀, ní bíbu àkàrà àti nínú àdúrà.

Read full chapter

The Fellowship of the Believers

42 They devoted themselves to the apostles’ teaching(A) and to fellowship, to the breaking of bread(B) and to prayer.(C)

Read full chapter

11 Nígbà tí ó sì tún gòkè lọ, ó sì jẹ oúnjẹ Olúwa, ó sì sọ̀rọ̀ pẹ́ títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́, nígbà náà ni ó sì lọ.

Read full chapter

11 Then he went upstairs again and broke bread(A) and ate. After talking until daylight, he left.

Read full chapter

35 Nígbà tí ó sì wí nǹkan wọ̀nyí, tí ó sì mú àkàrà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run níwájú gbogbo wọn: nígbà tí ó si bù ú, ó bẹ̀rẹ̀ sí i jẹ.

Read full chapter

35 After he said this, he took some bread and gave thanks to God in front of them all. Then he broke it(A) and began to eat.

Read full chapter