Add parallel Print Page Options

Bíbọ̀ ìjọba Ọlọ́run

20 (A)Nígbà tí àwọn Farisi bi í pé, nígbà wo ni ìjọba Ọlọ́run yóò dé, ó dá wọn lóhùn pé, “Ìjọba Ọlọ́run kì í wá pẹ̀lú ààmì:

Read full chapter

The Coming of the Kingdom of God(A)

20 Once, on being asked by the Pharisees when the kingdom of God would come,(B) Jesus replied, “The coming of the kingdom of God is not something that can be observed,

Read full chapter

Nítorí náà, nígbà tí wọ́n sì péjọpọ̀, wọn bi í léèrè pé, “Olúwa, láti ìgbà yí lọ ìwọ yóò ha mú ìjọba padà fún Israẹli bí?”

Read full chapter

Then they gathered around him and asked him, “Lord, are you at this time going to restore(A) the kingdom to Israel?”

Read full chapter