Add parallel Print Page Options

32 (A)Ohun tí ó ti rí tí ó sì ti gbọ́ èyí náà sì ni òun ń jẹ́rìí rẹ̀; kò sì sí ẹni tí ó gba ẹ̀rí rẹ̀.

Read full chapter

32 He testifies to what he has seen and heard,(A) but no one accepts his testimony.(B)

Read full chapter

14 Jesu dáhùn ó sì wí fún wọn pé, “Bí mo tilẹ̀ ń jẹ́rìí fún ara mi, òtítọ́ ni ẹ̀rí mi: nítorí tí mo mọ ibi tí mo ti wá, mo sì mọ ibi tí mo ń lọ; ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò lè mọ ibi tí mo ti wá, àti ibi tí mo ń lọ.

Read full chapter

14 Jesus answered, “Even if I testify on my own behalf, my testimony is valid, for I know where I came from and where I am going.(A) But you have no idea where I come from(B) or where I am going.

Read full chapter

47 Ẹni tí ń ṣe ti Ọlọ́run, a máa gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: nítorí èyí ni ẹ̀yin kò ṣe gbọ́, nítorí ẹ̀yin kì í ṣe ti Ọlọ́run.”

Read full chapter

47 Whoever belongs to God hears what God says.(A) The reason you do not hear is that you do not belong to God.”

Read full chapter

(A)Ti Ọlọ́run ni àwa: ẹni tí ó bá mọ Ọlọ́run, ó ń gbọ́ tiwa; ẹni tí kì í ṣe ti Ọlọ́run kò ni gbọ́ ti wa. Nípa èyí ni àwa mọ ẹ̀mí òtítọ́, àti ẹ̀mí èké.

Read full chapter

We are from God, and whoever knows God listens to us; but whoever is not from God does not listen to us.(A) This is how we recognize the Spirit[a] of truth(B) and the spirit of falsehood.(C)

Read full chapter

Footnotes

  1. 1 John 4:6 Or spirit