Add parallel Print Page Options

(A)Òun náà ní ó tọ Jesu wá ní òru, ó sì wí fún un pé, Rabbi, àwa mọ̀ pé olùkọ́ni láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ìwọ ń ṣe: nítorí pé kò sí ẹni tí ó lè ṣe iṣẹ́ ààmì wọ̀nyí tí ìwọ ń ṣe, bí kò ṣe pé Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀.

Read full chapter

He came to Jesus at night and said, “Rabbi,(A) we know(B) that you are a teacher who has come from God. For no one could perform the signs(C) you are doing if God were not with him.”(D)

Read full chapter

(A)Ẹni tí ó bá wí pé, “Èmi mọ̀ ọ́n,” tí kò sì pa òfin rẹ̀ mọ́, èké ni, òtítọ́ kò sì ṣí nínú rẹ̀.

Read full chapter

Whoever says, “I know him,”(A) but does not do what he commands is a liar, and the truth is not in that person.(B)

Read full chapter

11 Ṣùgbọ́n ẹni tí o bá kórìíra arákùnrin rẹ̀ ń gbé nínú òkùnkùn, ó sì ń rìn nínú òkùnkùn; kò sì mọ ibi tí òun ń lọ, nítorí tí òkùnkùn tí fọ́ ọ lójú.

Read full chapter

11 But anyone who hates a brother or sister(A) is in the darkness and walks around in the darkness.(B) They do not know where they are going, because the darkness has blinded them.(C)

Read full chapter