Añadir traducción en paralelo Imprimir Opciones de la página

33 “Èyí ni májẹ̀mú tí èmi yóò bá ilé Israẹli dá
    lẹ́yìn ìgbà náà,” ni Olúwa wí pé:
“Èmi yóò fi òfin mi sí ọkàn wọn,
    èmi ó sì kọ ọ́ sí àyà wọn.
Èmi ó jẹ́ Olúwa wọn;
    àwọn ó sì jẹ́ ènìyàn mi.

Read full chapter

Nítorí èyí báyìí ni ètùtù yóò ṣe wà
    fún ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu,
èyí ni yóò sì jẹ́ èso kíkún ti
    ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ rẹ:
Nígbà tí ó bá mú kí àwọn òkúta pẹpẹ
    dàbí òkúta ẹfun tí a fọ́ sí wẹ́wẹ́,
kì yóò sí ère Aṣerah tàbí pẹpẹ tùràrí
    tí yóò wà ní ìdúró.

Read full chapter