Font Size
Jeremiah 22:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Jeremiah 22:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
5 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá tẹ̀lé àṣẹ wọ̀nyí, mo búra fúnra mi pé ààfin yìí yóò di ìparun ni Olúwa wí.’ ”
Read full chapter
Saamu 118:26
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Saamu 118:26
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
26 Ìbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa.
Àwa ti fi ìbùkún fún ọ láti ilé Olúwa wá.
Luku 19:38
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 19:38
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
38 (A)Wí pé, “Olùbùkún ni ọba tí ó ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa!”
“Àlàáfíà ní ọ̀run, àti ògo ni òkè ọ̀run!”
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.