Add parallel Print Page Options

Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá tẹ̀lé àṣẹ wọ̀nyí, mo búra fúnra mi pé ààfin yìí yóò di ìparun ni Olúwa wí.’ ”

Read full chapter

But if you do not obey(A) these commands, declares the Lord, I swear(B) by myself that this palace will become a ruin.’”

Read full chapter

26 Ìbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa.
    Àwa ti fi ìbùkún fún ọ láti ilé Olúwa wá.

Read full chapter

26 Blessed is he who comes(A) in the name of the Lord.
    From the house of the Lord we bless you.[a](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Psalm 118:26 The Hebrew is plural.

38 (A)Wí pé, “Olùbùkún ni ọba tí ó ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa!”

“Àlàáfíà ní ọ̀run, àti ògo ni òkè ọ̀run!”

Read full chapter

38 “Blessed is the king who comes in the name of the Lord!”[a](A)

“Peace in heaven and glory in the highest!”(B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Luke 19:38 Psalm 118:26