Add parallel Print Page Options

17 (A)Ní òpin àádọ́rin ọdún náà, Olúwa yóò bá Tire jà. Òun yóò sì padà sí àyálò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí panṣágà, yóò sì máa ṣe òwò rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ilẹ̀ ọba tí ó wà ní ilẹ̀ ayé.

Read full chapter

17 At the end of seventy years,(A) the Lord will deal with Tyre. She will return to her lucrative prostitution(B) and will ply her trade with all the kingdoms on the face of the earth.(C)

Read full chapter

Ago ìbínú Ọlọ́run

15 (A)Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí fún mi: “Gba ago yìí ní ọwọ́ mí tí ó kún fún ọtí wáìnì ìbínú mi, kí o sì mú gbogbo orílẹ̀-èdè ti mo rán ọ sí mu ún. 16 Nígbà tí wọ́n bá mu ún, wọn yóò ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n: bẹ́ẹ̀ ni kí wọ́n di aṣiwèrè nítorí idà tí yóò ránṣẹ́ sí àárín wọn.”

Read full chapter

The Cup of God’s Wrath

15 This is what the Lord, the God of Israel, said to me: “Take from my hand this cup(A) filled with the wine of my wrath and make all the nations to whom I send(B) you drink it. 16 When they drink(C) it, they will stagger(D) and go mad(E) because of the sword(F) I will send among them.”

Read full chapter