Add parallel Print Page Options

Àìronúpìwàdà Israẹli

“Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa
ó ti fà wá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ
    ṣùgbọ́n yóò mú wa láradá
Ó ti pa wá lára
    ṣùgbọ́n yóò dí ojú ọgbẹ́ wa.
Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí
    ní ọjọ́ kẹta yóò mú wa padà bọ̀ sípò
    kí a ba à le wá gbé níwájú rẹ̀
Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa
    Ẹ jẹ́ kí a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ọ́n.
Gẹ́gẹ́ bí oòrùn ṣe ń yọ,
    Yóò jáde;
Yóò tọ̀ wá wá bí òjò
    bí òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀.”

“Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu?
    Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Juda?
Ìfẹ́ rẹ dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀
    bí ìrì ìdájí tí ó kọjá lọ kíákíá.
Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì.
    Mo pa yín pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹnu mi
    Ìdájọ́ mi tàn bí i mọ̀nàmọ́ná lórí yín
(A)Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ;
    àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ sísun lọ.
Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú
    wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí mi níbẹ̀.
Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú
    tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀, a sí ti fi ẹ̀ṣẹ̀ bà á jẹ́.
Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn
    bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà, ń parapọ̀;
tí wọ́n sì ń pànìyàn lójú ọ̀nà tó lọ sí Ṣekemu,
    tí wọ́n sì ń dá ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ni lójú.
10 Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù
    ní ilé Israẹli.
Níbẹ̀ Efraimu, fi ara rẹ̀ fún àgbèrè
    Israẹli sì di aláìmọ́.

11 “Àti fún ìwọ, Juda
    A ti yan ọjọ́ ìkórè rẹ.

“Nígbà tí mo bá fẹ́ dá ohun ìní àwọn ènìyàn mi padà,

Israel Unrepentant

“Come, let us return(A) to the Lord.
He has torn us to pieces(B)
    but he will heal us;(C)
he has injured us
    but he will bind up our wounds.(D)
After two days he will revive us;(E)
    on the third day(F) he will restore(G) us,
    that we may live in his presence.
Let us acknowledge the Lord;
    let us press on to acknowledge him.
As surely as the sun rises,
    he will appear;
he will come to us like the winter rains,(H)
    like the spring rains that water the earth.(I)

“What can I do with you, Ephraim?(J)
    What can I do with you, Judah?
Your love is like the morning mist,
    like the early dew that disappears.(K)
Therefore I cut you in pieces with my prophets,
    I killed you with the words of my mouth(L)
    then my judgments go forth like the sun.[a](M)
For I desire mercy, not sacrifice,(N)
    and acknowledgment(O) of God rather than burnt offerings.(P)
As at Adam,[b] they have broken the covenant;(Q)
    they were unfaithful(R) to me there.
Gilead is a city of evildoers,(S)
    stained with footprints of blood.
As marauders lie in ambush for a victim,(T)
    so do bands of priests;
they murder(U) on the road to Shechem,
    carrying out their wicked schemes.(V)
10 I have seen a horrible(W) thing in Israel:
    There Ephraim is given to prostitution,
    Israel is defiled.(X)

11 “Also for you, Judah,
    a harvest(Y) is appointed.

“Whenever I would restore the fortunes(Z) of my people,

Footnotes

  1. Hosea 6:5 The meaning of the Hebrew for this line is uncertain.
  2. Hosea 6:7 Or Like Adam; or Like human beings