Add parallel Print Page Options

Ìparí àwọn ọ̀rọ̀ ìyànjú náà

13 Kí ìfẹ́ ará kí o wà títí. (A)Ẹ má ṣe gbàgbé láti máa ṣe àlejò; nítorí pé nípa bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlòmíràn ṣe àwọn angẹli ní àlejò láìmọ̀. Ẹ máa rántí àwọn òǹdè bí ẹni tí a dè pẹ̀lú wọn, àti àwọn tí a ń pọn lójú bí ẹ̀yin tìkára yín pẹ̀lú tí ń bẹ nínú ara.

Kí ìgbéyàwó lọ́lá láàrín gbogbo ènìyàn, kí àkéte si jẹ́ aláìléèérí: Nítorí àwọn àgbèrè àti àwọn panṣágà ni Ọlọ́run yóò dá lẹ́jọ́. (B)Kí ọkàn yín má ṣe fà sí ìfẹ́ owó, ki ohun tí ẹ ní tó yin; nítorí òun tìkára rẹ̀ ti wí pé,

“Èmi kò jẹ́ fi ọ́ sílẹ̀,
    bẹ́ẹ̀ ni èmi kò jẹ́ kọ̀ ọ́ sílẹ̀.”

(C)Nítorí náà ni àwa ṣe ń fi ìgboyà wí pé,

“Olúwa ni olùrànlọ́wọ́ mi, èmi kì yóò bẹ̀rù;
    kín ni ènìyàn lè ṣe sí mi?”

Ẹ máa rántí àwọn tiwọn jẹ́ aṣáájú yín, tiwọn ti sọ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún yín; kí ẹ máa ro òpin ìwà ayé wọn, kí ẹ sì máa ṣe àfarawé ìgbàgbọ́ wọn. Jesu Kristi ọ̀kan náà ni lánàá, àti lónìí, àti títí láé.

Ẹ má ṣe jẹ́ kí a fi onírúurú àti àjèjì ẹ̀kọ́ gbá yin kiri. Nítorí ó dára kí a mú yin lọ́kàn le nípa oore-ọ̀fẹ́, kì í ṣe nípa oúnjẹ nínú èyí tí àwọn tí ó ti rìn nínú wọn kò ní èrè. 10 Àwa ní pẹpẹ kan, níbi èyí tí àwọn ti ń sin àgọ́ kò ni agbára láti máa jẹ.

11 (D)Nítorí nígbà tí olórí àlùfáà bá mú ẹ̀jẹ̀ àwọn ẹran wá si ibi mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ìrúbọ ẹ̀ṣẹ̀, òkú àwọn ẹran náà ni a o sun lẹ́yìn ibùdó. 12 Nítorí náà Jesu pẹ̀lú, kí ó lè fi ẹ̀jẹ̀ ara rẹ̀ sọ àwọn ènìyàn di mímọ́, ó jìyà lẹ́yìn ibodè. 13 Nítorí náà ẹ jẹ́ kí a jáde tọ̀ ọ́ lọ lẹ́yìn ibùdó, kí a máa ru ẹ̀gàn rẹ̀. 14 Nítorí pé àwa kò ní ìlú tí o wa títí níhìn-ín, ṣùgbọ́n àwa ń wá èyí tí ń bọ.

15 (E)Ǹjẹ́ nípasẹ̀ rẹ̀, ẹ jẹ́ kí a máa rú ẹbọ ìyìn si Ọlọ́run nígbà gbogbo, èyí yìí ni èso ètè wa, tí ń jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀. 16 Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe gbàgbé láti máa ṣoore àti láti máa pín fun ni nítorí irú ẹbọ wọ̀nyí ni inú Ọlọ́run dùn sí jọjọ.

17 Ẹ máa gbọ́ ti àwọn tí ń ṣe olórí yín, kí ẹ sì máa tẹríba fún wọ́n: Nítorí wọn ń ṣọ́ ẹ̀ṣọ́ nítorí ọkàn yín, bí àwọn ti yóò ṣe ìṣirò, kí wọn lè fi ayọ̀ ṣe èyí, kì í ṣe pẹ̀lú ìbànújẹ́, nítorí èyí yìí yóò jẹ àìlérè fún yín.

18 Ẹ máa gbàdúrà fún wa: nítorí àwa gbàgbọ́ pé àwa ni ẹ̀rí ọkàn rere, a sì ń fẹ́ láti máa hùwà títọ́ nínú ohun gbogbo. 19 Ṣùgbọ́n èmi ń bẹ̀ yín gidigidi sí i láti máa ṣe èyí, kí a ba lè tètè fi mi fún yín padà.

20 (F)Ǹjẹ́ Ọlọ́run àlàáfíà, ẹni tí o tún mu olùṣọ́-àgùntàn ńlá ti àwọn àgùntàn, ti inú òkú wá, nípa ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú ayérayé, àní Olúwa wa Jesu. 21 Kí ó mú yín pé nínú iṣẹ́ rere gbogbo láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀, kí ó máa ṣiṣẹ́ ohun tí i ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú rẹ̀ nínú yín nípasẹ̀ Jesu Kristi; ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín.

22 Èmi sì ń bẹ̀ yín ará, ẹ gbà ọ̀rọ̀ ìyànjú mi; nítorí ìwé kúkúrú ni mo kọ sí yín.

23 Ẹ mọ pé a sá titu Timotiu arákùnrin wa sílẹ̀; bí ó ba tètè dé, èmí pẹ̀lú rẹ̀ yóò rí yín, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́.

24 Ẹ ki gbogbo àwọn tí ń ṣe olórí yín, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́.

Àwọn tí o ti Itali wá ki yín.

25 Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú gbogbo yín.

Concluding Exhortations

13 Keep on loving one another as brothers and sisters.(A) Do not forget to show hospitality to strangers,(B) for by so doing some people have shown hospitality to angels without knowing it.(C) Continue to remember those in prison(D) as if you were together with them in prison, and those who are mistreated as if you yourselves were suffering.

Marriage should be honored by all,(E) and the marriage bed kept pure, for God will judge the adulterer and all the sexually immoral.(F) Keep your lives free from the love of money(G) and be content with what you have,(H) because God has said,

“Never will I leave you;
    never will I forsake you.”[a](I)

So we say with confidence,

“The Lord is my helper; I will not be afraid.
    What can mere mortals do to me?”[b](J)

Remember your leaders,(K) who spoke the word of God(L) to you. Consider the outcome of their way of life and imitate(M) their faith. Jesus Christ is the same yesterday and today and forever.(N)

Do not be carried away by all kinds of strange teachings.(O) It is good for our hearts to be strengthened(P) by grace, not by eating ceremonial foods,(Q) which is of no benefit to those who do so.(R) 10 We have an altar from which those who minister at the tabernacle(S) have no right to eat.(T)

11 The high priest carries the blood of animals into the Most Holy Place as a sin offering,(U) but the bodies are burned outside the camp.(V) 12 And so Jesus also suffered outside the city gate(W) to make the people holy(X) through his own blood.(Y) 13 Let us, then, go to him(Z) outside the camp, bearing the disgrace he bore.(AA) 14 For here we do not have an enduring city,(AB) but we are looking for the city that is to come.(AC)

15 Through Jesus, therefore, let us continually offer to God a sacrifice(AD) of praise—the fruit of lips(AE) that openly profess his name. 16 And do not forget to do good and to share with others,(AF) for with such sacrifices(AG) God is pleased.

17 Have confidence in your leaders(AH) and submit to their authority, because they keep watch over you(AI) as those who must give an account. Do this so that their work will be a joy, not a burden, for that would be of no benefit to you.

18 Pray for us.(AJ) We are sure that we have a clear conscience(AK) and desire to live honorably in every way. 19 I particularly urge you to pray so that I may be restored to you soon.(AL)

Benediction and Final Greetings

20 Now may the God of peace,(AM) who through the blood of the eternal covenant(AN) brought back from the dead(AO) our Lord Jesus, that great Shepherd of the sheep,(AP) 21 equip you with everything good for doing his will,(AQ) and may he work in us(AR) what is pleasing to him,(AS) through Jesus Christ, to whom be glory for ever and ever. Amen.(AT)

22 Brothers and sisters, I urge you to bear with my word of exhortation, for in fact I have written to you quite briefly.(AU)

23 I want you to know that our brother Timothy(AV) has been released. If he arrives soon, I will come with him to see you.

24 Greet all your leaders(AW) and all the Lord’s people. Those from Italy(AX) send you their greetings.

25 Grace be with you all.(AY)

Footnotes

  1. Hebrews 13:5 Deut. 31:6
  2. Hebrews 13:6 Psalm 118:6,7

13 Let brotherly love continue.

Be not forgetful to entertain strangers: for thereby some have entertained angels unawares.

Remember them that are in bonds, as bound with them; and them which suffer adversity, as being yourselves also in the body.

Marriage is honourable in all, and the bed undefiled: but whoremongers and adulterers God will judge.

Let your conversation be without covetousness; and be content with such things as ye have: for he hath said, I will never leave thee, nor forsake thee.

So that we may boldly say, The Lord is my helper, and I will not fear what man shall do unto me.

Remember them which have the rule over you, who have spoken unto you the word of God: whose faith follow, considering the end of their conversation.

Jesus Christ the same yesterday, and to day, and for ever.

Be not carried about with divers and strange doctrines. For it is a good thing that the heart be established with grace; not with meats, which have not profited them that have been occupied therein.

10 We have an altar, whereof they have no right to eat which serve the tabernacle.

11 For the bodies of those beasts, whose blood is brought into the sanctuary by the high priest for sin, are burned without the camp.

12 Wherefore Jesus also, that he might sanctify the people with his own blood, suffered without the gate.

13 Let us go forth therefore unto him without the camp, bearing his reproach.

14 For here have we no continuing city, but we seek one to come.

15 By him therefore let us offer the sacrifice of praise to God continually, that is, the fruit of our lips giving thanks to his name.

16 But to do good and to communicate forget not: for with such sacrifices God is well pleased.

17 Obey them that have the rule over you, and submit yourselves: for they watch for your souls, as they that must give account, that they may do it with joy, and not with grief: for that is unprofitable for you.

18 Pray for us: for we trust we have a good conscience, in all things willing to live honestly.

19 But I beseech you the rather to do this, that I may be restored to you the sooner.

20 Now the God of peace, that brought again from the dead our Lord Jesus, that great shepherd of the sheep, through the blood of the everlasting covenant,

21 Make you perfect in every good work to do his will, working in you that which is wellpleasing in his sight, through Jesus Christ; to whom be glory for ever and ever. Amen.

22 And I beseech you, brethren, suffer the word of exhortation: for I have written a letter unto you in few words.

23 Know ye that our brother Timothy is set at liberty; with whom, if he come shortly, I will see you.

24 Salute all them that have the rule over you, and all the saints. They of Italy salute you.

25 Grace be with you all. Amen.

Ìparí àwọn ọ̀rọ̀ ìyànjú náà

13 Kí ìfẹ́ ará kí o wà títí. (A)Ẹ má ṣe gbàgbé láti máa ṣe àlejò; nítorí pé nípa bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlòmíràn ṣe àwọn angẹli ní àlejò láìmọ̀. Ẹ máa rántí àwọn òǹdè bí ẹni tí a dè pẹ̀lú wọn, àti àwọn tí a ń pọn lójú bí ẹ̀yin tìkára yín pẹ̀lú tí ń bẹ nínú ara.

Kí ìgbéyàwó lọ́lá láàrín gbogbo ènìyàn, kí àkéte si jẹ́ aláìléèérí: Nítorí àwọn àgbèrè àti àwọn panṣágà ni Ọlọ́run yóò dá lẹ́jọ́. (B)Kí ọkàn yín má ṣe fà sí ìfẹ́ owó, ki ohun tí ẹ ní tó yin; nítorí òun tìkára rẹ̀ ti wí pé,

“Èmi kò jẹ́ fi ọ́ sílẹ̀,
    bẹ́ẹ̀ ni èmi kò jẹ́ kọ̀ ọ́ sílẹ̀.”

(C)Nítorí náà ni àwa ṣe ń fi ìgboyà wí pé,

“Olúwa ni olùrànlọ́wọ́ mi, èmi kì yóò bẹ̀rù;
    kín ni ènìyàn lè ṣe sí mi?”

Ẹ máa rántí àwọn tiwọn jẹ́ aṣáájú yín, tiwọn ti sọ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún yín; kí ẹ máa ro òpin ìwà ayé wọn, kí ẹ sì máa ṣe àfarawé ìgbàgbọ́ wọn. Jesu Kristi ọ̀kan náà ni lánàá, àti lónìí, àti títí láé.

Ẹ má ṣe jẹ́ kí a fi onírúurú àti àjèjì ẹ̀kọ́ gbá yin kiri. Nítorí ó dára kí a mú yin lọ́kàn le nípa oore-ọ̀fẹ́, kì í ṣe nípa oúnjẹ nínú èyí tí àwọn tí ó ti rìn nínú wọn kò ní èrè. 10 Àwa ní pẹpẹ kan, níbi èyí tí àwọn ti ń sin àgọ́ kò ni agbára láti máa jẹ.

11 (D)Nítorí nígbà tí olórí àlùfáà bá mú ẹ̀jẹ̀ àwọn ẹran wá si ibi mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ìrúbọ ẹ̀ṣẹ̀, òkú àwọn ẹran náà ni a o sun lẹ́yìn ibùdó. 12 Nítorí náà Jesu pẹ̀lú, kí ó lè fi ẹ̀jẹ̀ ara rẹ̀ sọ àwọn ènìyàn di mímọ́, ó jìyà lẹ́yìn ibodè. 13 Nítorí náà ẹ jẹ́ kí a jáde tọ̀ ọ́ lọ lẹ́yìn ibùdó, kí a máa ru ẹ̀gàn rẹ̀. 14 Nítorí pé àwa kò ní ìlú tí o wa títí níhìn-ín, ṣùgbọ́n àwa ń wá èyí tí ń bọ.

15 (E)Ǹjẹ́ nípasẹ̀ rẹ̀, ẹ jẹ́ kí a máa rú ẹbọ ìyìn si Ọlọ́run nígbà gbogbo, èyí yìí ni èso ètè wa, tí ń jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀. 16 Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe gbàgbé láti máa ṣoore àti láti máa pín fun ni nítorí irú ẹbọ wọ̀nyí ni inú Ọlọ́run dùn sí jọjọ.

17 Ẹ máa gbọ́ ti àwọn tí ń ṣe olórí yín, kí ẹ sì máa tẹríba fún wọ́n: Nítorí wọn ń ṣọ́ ẹ̀ṣọ́ nítorí ọkàn yín, bí àwọn ti yóò ṣe ìṣirò, kí wọn lè fi ayọ̀ ṣe èyí, kì í ṣe pẹ̀lú ìbànújẹ́, nítorí èyí yìí yóò jẹ àìlérè fún yín.

18 Ẹ máa gbàdúrà fún wa: nítorí àwa gbàgbọ́ pé àwa ni ẹ̀rí ọkàn rere, a sì ń fẹ́ láti máa hùwà títọ́ nínú ohun gbogbo. 19 Ṣùgbọ́n èmi ń bẹ̀ yín gidigidi sí i láti máa ṣe èyí, kí a ba lè tètè fi mi fún yín padà.

20 (F)Ǹjẹ́ Ọlọ́run àlàáfíà, ẹni tí o tún mu olùṣọ́-àgùntàn ńlá ti àwọn àgùntàn, ti inú òkú wá, nípa ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú ayérayé, àní Olúwa wa Jesu. 21 Kí ó mú yín pé nínú iṣẹ́ rere gbogbo láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀, kí ó máa ṣiṣẹ́ ohun tí i ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú rẹ̀ nínú yín nípasẹ̀ Jesu Kristi; ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín.

22 Èmi sì ń bẹ̀ yín ará, ẹ gbà ọ̀rọ̀ ìyànjú mi; nítorí ìwé kúkúrú ni mo kọ sí yín.

23 Ẹ mọ pé a sá titu Timotiu arákùnrin wa sílẹ̀; bí ó ba tètè dé, èmí pẹ̀lú rẹ̀ yóò rí yín, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́.

24 Ẹ ki gbogbo àwọn tí ń ṣe olórí yín, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́.

Àwọn tí o ti Itali wá ki yín.

25 Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú gbogbo yín.

Concluding Exhortations

13 Keep on loving one another as brothers and sisters.(A) Do not forget to show hospitality to strangers,(B) for by so doing some people have shown hospitality to angels without knowing it.(C) Continue to remember those in prison(D) as if you were together with them in prison, and those who are mistreated as if you yourselves were suffering.

Marriage should be honored by all,(E) and the marriage bed kept pure, for God will judge the adulterer and all the sexually immoral.(F) Keep your lives free from the love of money(G) and be content with what you have,(H) because God has said,

“Never will I leave you;
    never will I forsake you.”[a](I)

So we say with confidence,

“The Lord is my helper; I will not be afraid.
    What can mere mortals do to me?”[b](J)

Remember your leaders,(K) who spoke the word of God(L) to you. Consider the outcome of their way of life and imitate(M) their faith. Jesus Christ is the same yesterday and today and forever.(N)

Do not be carried away by all kinds of strange teachings.(O) It is good for our hearts to be strengthened(P) by grace, not by eating ceremonial foods,(Q) which is of no benefit to those who do so.(R) 10 We have an altar from which those who minister at the tabernacle(S) have no right to eat.(T)

11 The high priest carries the blood of animals into the Most Holy Place as a sin offering,(U) but the bodies are burned outside the camp.(V) 12 And so Jesus also suffered outside the city gate(W) to make the people holy(X) through his own blood.(Y) 13 Let us, then, go to him(Z) outside the camp, bearing the disgrace he bore.(AA) 14 For here we do not have an enduring city,(AB) but we are looking for the city that is to come.(AC)

15 Through Jesus, therefore, let us continually offer to God a sacrifice(AD) of praise—the fruit of lips(AE) that openly profess his name. 16 And do not forget to do good and to share with others,(AF) for with such sacrifices(AG) God is pleased.

17 Have confidence in your leaders(AH) and submit to their authority, because they keep watch over you(AI) as those who must give an account. Do this so that their work will be a joy, not a burden, for that would be of no benefit to you.

18 Pray for us.(AJ) We are sure that we have a clear conscience(AK) and desire to live honorably in every way. 19 I particularly urge you to pray so that I may be restored to you soon.(AL)

Benediction and Final Greetings

20 Now may the God of peace,(AM) who through the blood of the eternal covenant(AN) brought back from the dead(AO) our Lord Jesus, that great Shepherd of the sheep,(AP) 21 equip you with everything good for doing his will,(AQ) and may he work in us(AR) what is pleasing to him,(AS) through Jesus Christ, to whom be glory for ever and ever. Amen.(AT)

22 Brothers and sisters, I urge you to bear with my word of exhortation, for in fact I have written to you quite briefly.(AU)

23 I want you to know that our brother Timothy(AV) has been released. If he arrives soon, I will come with him to see you.

24 Greet all your leaders(AW) and all the Lord’s people. Those from Italy(AX) send you their greetings.

25 Grace be with you all.(AY)

Footnotes

  1. Hebrews 13:5 Deut. 31:6
  2. Hebrews 13:6 Psalm 118:6,7

13 Let brotherly love continue.

Be not forgetful to entertain strangers: for thereby some have entertained angels unawares.

Remember them that are in bonds, as bound with them; and them which suffer adversity, as being yourselves also in the body.

Marriage is honourable in all, and the bed undefiled: but whoremongers and adulterers God will judge.

Let your conversation be without covetousness; and be content with such things as ye have: for he hath said, I will never leave thee, nor forsake thee.

So that we may boldly say, The Lord is my helper, and I will not fear what man shall do unto me.

Remember them which have the rule over you, who have spoken unto you the word of God: whose faith follow, considering the end of their conversation.

Jesus Christ the same yesterday, and to day, and for ever.

Be not carried about with divers and strange doctrines. For it is a good thing that the heart be established with grace; not with meats, which have not profited them that have been occupied therein.

10 We have an altar, whereof they have no right to eat which serve the tabernacle.

11 For the bodies of those beasts, whose blood is brought into the sanctuary by the high priest for sin, are burned without the camp.

12 Wherefore Jesus also, that he might sanctify the people with his own blood, suffered without the gate.

13 Let us go forth therefore unto him without the camp, bearing his reproach.

14 For here have we no continuing city, but we seek one to come.

15 By him therefore let us offer the sacrifice of praise to God continually, that is, the fruit of our lips giving thanks to his name.

16 But to do good and to communicate forget not: for with such sacrifices God is well pleased.

17 Obey them that have the rule over you, and submit yourselves: for they watch for your souls, as they that must give account, that they may do it with joy, and not with grief: for that is unprofitable for you.

18 Pray for us: for we trust we have a good conscience, in all things willing to live honestly.

19 But I beseech you the rather to do this, that I may be restored to you the sooner.

20 Now the God of peace, that brought again from the dead our Lord Jesus, that great shepherd of the sheep, through the blood of the everlasting covenant,

21 Make you perfect in every good work to do his will, working in you that which is wellpleasing in his sight, through Jesus Christ; to whom be glory for ever and ever. Amen.

22 And I beseech you, brethren, suffer the word of exhortation: for I have written a letter unto you in few words.

23 Know ye that our brother Timothy is set at liberty; with whom, if he come shortly, I will see you.

24 Salute all them that have the rule over you, and all the saints. They of Italy salute you.

25 Grace be with you all. Amen.