Add parallel Print Page Options

(A)Báyìí ni Ọlọ́run parí dídá àwọn ọ̀run àti ayé, àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀.

(B)(C) Ní ọjọ́ keje Ọlọ́run sì parí iṣẹ́ rẹ̀ tí ó ti ń ṣe; ó sì sinmi ní ọjọ́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo tí ó ti ń ṣe. Ọlọ́run sì súre fún ọjọ́ keje, ó sì yà á sí mímọ́, nítorí pé ní ọjọ́ náà ni ó sinmi kúrò nínú iṣẹ́ dídá ayé tí ó ti ń ṣe.

Adamu àti Efa

Èyí ni ìtàn bí Ọlọ́run ṣe dá àwọn ọ̀run àti ayé nígbà tí ó dá wọn. Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run dá ayé àti àwọn ọ̀run.

Kò sí igi igbó kan ní orí ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ewéko igbó kan tí ó tí ì hù jáde ní ilẹ̀, nítorí Olúwa Ọlọ́run kò tí ì rọ̀jò sórí ilẹ̀, kò sì sí ènìyàn láti ro ilẹ̀. Ṣùgbọ́n ìsun omi ń jáde láti ilẹ̀, ó sì ń bu omi rin gbogbo ilẹ̀. (D)Olúwa Ọlọ́run sì fi erùpẹ̀ ilẹ̀ mọ ènìyàn, ó si mí èémí ìyè sí ihò imú rẹ̀, ènìyàn sì di alààyè ọkàn.

Olúwa Ọlọ́run sì gbin ọgbà kan sí Edeni ní ìhà ìlà-oòrùn, níbẹ̀ ni ó fi ọkùnrin náà tí ó ti dá sí. (E)Olúwa Ọlọ́run sì mú kí onírúurú igi hù jáde láti inú ilẹ̀: àwọn igi tí ó dùn ún wò lójú, tí ó sì dára fún oúnjẹ. Ní àárín ọgbà náà ni igi ìyè àti igi tí ń mú ènìyàn mọ rere àti búburú wà.

10 Odò kan sì ń ti Edeni sàn wá láti bu omi rin ọgbà náà, láti ibẹ̀ ni odò náà gbé ya sí ipa mẹ́rin. 11 Orúkọ èkínní ni Pisoni: òun ni ó sàn yí gbogbo ilẹ̀ Hafila ká, níbi tí wúrà gbé wà. 12 (Wúrà ilẹ̀ náà dára, òjìá (bedeliumu) àti òkúta (óníkìsì) oníyebíye wà níbẹ̀ pẹ̀lú). 13 Orúkọ odò kejì ni Gihoni: òun ni ó sàn yí gbogbo ilẹ̀ Kuṣi ká. 14 Orúkọ odò kẹta ni Tigirisi: òun ni ó sàn ní apá ìlà-oòrùn ilẹ̀ Asiria. Odò kẹrin ni Eufurate.

15 Olúwa Ọlọ́run mú ọkùnrin náà sínú ọgbà Edeni láti máa ṣe iṣẹ́ níbẹ̀, kí ó sì máa ṣe ìtọ́jú rẹ̀. 16 Olúwa Ọlọ́run sì pàṣẹ fún ọkùnrin náà pé, “Ìwọ lè jẹ lára èyíkéyìí èso àwọn igi inú ọgbà; 17 ṣùgbọ́n ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ nínú èso igi ìmọ̀ rere àti èso igi ìmọ̀ búburú, nítorí ní ọjọ́ tí ìwọ bá jẹ ẹ́ ni ìwọ yóò kùú.”

18 Olúwa Ọlọ́run wí pé, “Kò dára kí ọkùnrin wà ní òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànlọ́wọ́ tí ó rí bí i rẹ̀ fún un.”

19 Lẹ́yìn tí Olúwa Ọlọ́run ti dá àwọn ẹranko inú igbó àti gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run láti inú erùpẹ̀ ilẹ̀. Ó sì kó wọn tọ ọkùnrin náà wá láti wo orúkọ tí yóò sọ wọ́n; orúkọ tí ó sì sọ gbogbo ẹ̀dá alààyè náà ni wọ́n ń jẹ́. 20 Gbogbo ohun ọ̀sìn, ẹyẹ ojú ọ̀run àti gbogbo ẹranko igbó ni ọkùnrin náà sọ ní orúkọ.

Ṣùgbọ́n fún Adamu ni a kò rí olùrànlọ́wọ́ tí ó rí bí i rẹ̀. 21 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run mú kí ọkùnrin náà sùn fọnfọn; nígbà tí ó sì ń sùn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó sì fi ẹran-ara bò ó padà. 22 Olúwa Ọlọ́run sì dá obìnrin láti inú egungun tí ó yọ ní ìhà ọkùnrin náà, Ó sì mu obìnrin náà tọ̀ ọ́ wá.

23 Ọkùnrin náà sì wí pé,

“Èyí ni egungun láti inú egungun mi
    àti ẹran-ara nínú ẹran-ara mi;
‘obìnrin’ ni a ó máa pè é,
    nítorí a mú un jáde láti ara ọkùnrin.”

24 (F)Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò sì dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò sì di ara kan.

25 Ọkùnrin náà àti aya rẹ̀ sì wà ní ìhòhò, ojú kò sì tì wọ́n.

Thus the heavens and the earth were completed in all their vast array.(A)

By the seventh day(B) God had finished the work he had been doing; so on the seventh day he rested from all his work.(C) Then God blessed the seventh day and made it holy,(D) because on it he rested(E) from all the work of creating(F) that he had done.

Adam and Eve

This is the account(G) of the heavens and the earth when they were created,(H) when the Lord God made the earth and the heavens.

Now no shrub had yet appeared on the earth[a] and no plant had yet sprung up,(I) for the Lord God had not sent rain on the earth(J) and there was no one to work the ground, but streams[b] came up from the earth and watered the whole surface of the ground. Then the Lord God formed(K) a man[c](L) from the dust(M) of the ground(N) and breathed into his nostrils the breath(O) of life,(P) and the man became a living being.(Q)

Now the Lord God had planted a garden in the east, in Eden;(R) and there he put the man he had formed. The Lord God made all kinds of trees grow out of the ground—trees(S) that were pleasing to the eye and good for food. In the middle of the garden were the tree of life(T) and the tree of the knowledge of good and evil.(U)

10 A river(V) watering the garden flowed from Eden;(W) from there it was separated into four headwaters. 11 The name of the first is the Pishon; it winds through the entire land of Havilah,(X) where there is gold. 12 (The gold of that land is good; aromatic resin[d](Y) and onyx are also there.) 13 The name of the second river is the Gihon; it winds through the entire land of Cush.[e] 14 The name of the third river is the Tigris;(Z) it runs along the east side of Ashur. And the fourth river is the Euphrates.(AA)

15 The Lord God took the man and put him in the Garden of Eden(AB) to work it and take care of it. 16 And the Lord God commanded the man, “You are free to eat from any tree in the garden;(AC) 17 but you must not eat from the tree of the knowledge of good and evil,(AD) for when you eat from it you will certainly die.”(AE)

18 The Lord God said, “It is not good for the man to be alone. I will make a helper suitable for him.”(AF)

19 Now the Lord God had formed out of the ground all the wild animals(AG) and all the birds in the sky.(AH) He brought them to the man to see what he would name them; and whatever the man called(AI) each living creature,(AJ) that was its name. 20 So the man gave names to all the livestock, the birds in the sky and all the wild animals.

But for Adam[f] no suitable helper(AK) was found. 21 So the Lord God caused the man to fall into a deep sleep;(AL) and while he was sleeping, he took one of the man’s ribs[g] and then closed up the place with flesh. 22 Then the Lord God made a woman from the rib[h](AM) he had taken out of the man, and he brought her to the man.

23 The man said,

“This is now bone of my bones
    and flesh of my flesh;(AN)
she shall be called(AO) ‘woman,’
    for she was taken out of man.(AP)

24 That is why a man leaves his father and mother and is united(AQ) to his wife, and they become one flesh.(AR)

25 Adam and his wife were both naked,(AS) and they felt no shame.

Footnotes

  1. Genesis 2:5 Or land; also in verse 6
  2. Genesis 2:6 Or mist
  3. Genesis 2:7 The Hebrew for man (adam) sounds like and may be related to the Hebrew for ground (adamah); it is also the name Adam (see verse 20).
  4. Genesis 2:12 Or good; pearls
  5. Genesis 2:13 Possibly southeast Mesopotamia
  6. Genesis 2:20 Or the man
  7. Genesis 2:21 Or took part of the man’s side
  8. Genesis 2:22 Or part