Add parallel Print Page Options

“ ‘Nítorí báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí:

“ ‘Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà,
    fún ìkòkò náà tí èérí rẹ̀ wà nínú rẹ̀,
tí èérí kò dà kúrò lójú rẹ̀!
    Mú ẹran náà jáde ní ekìrí ekìrí
    má ṣe ṣà wọ́n mú.

“ ‘Nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ó ta sílẹ̀ wà ní àárín rẹ̀;
    à á sí orí àpáta kan lásán
kò dà á sí orí ilẹ̀,
    níbi ti erùpẹ̀ yóò ti bò ó
Láti bá à le jẹ́ kí ìbínú kí ó dé láti gbẹ̀san
    mo da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí orí àpáta kan lásán,
    kí o ma bà á wà ni bíbò.

Read full chapter