Font Size
Esekiẹli 20:16
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Esekiẹli 20:16
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
16 Nítorí pé, wọn kọ òfin mi sílẹ̀, wọn kò sì tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn sọ ọjọ́ ìsinmi mi dí aláìmọ́. Nítorí pé tọkàntọkàn ni wọn ń tẹ̀lé òrìṣà wọn.
Read full chapter
Esekiẹli 23:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Esekiẹli 23:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Lefitiku 19:16
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Lefitiku 19:16
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
16 “ ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ máa ṣèyíṣọ̀hún bí olóòfófó láàrín àwọn ènìyàn rẹ.
“ ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ohunkóhun tí yóò fi ẹ̀mí aládùúgbò rẹ wéwu: Èmi ni Olúwa.
Read full chapter
Deuteronomi 5:20
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Deuteronomi 5:20
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
20 Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí ẹnìkejì rẹ.
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.