Add parallel Print Page Options

Ó sì gbà wọ́n ní ọwọ́ wọn, ó sì fi ṣe ohun ọnà fínfín, ó sì dà á ní àwòrán ẹgbọrọ màlúù. Nígbà náà ni wọn wí pé, “Israẹli, wọ̀nyí ni òrìṣà, ti ó mú un yín jáde wá láti Ejibiti.”

Read full chapter

He took what they handed him and made it into an idol(A) cast in the shape of a calf,(B) fashioning it with a tool. Then they said, “These are your gods,[a](C) Israel, who brought you up out of Egypt.”(D)

Read full chapter

Footnotes

  1. Exodus 32:4 Or This is your god; also in verse 8

(A)Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn dìde ní kùtùkùtù ọjọ́ kejì, wọ́n sì rú ẹbọ sísun, wọ́n sì mú ẹbọ àlàáfíà wá. Lẹ́yìn náà wọ́n jókòó láti jẹ àti láti mu, wọ́n sì dìde láti ṣeré.

Read full chapter

So the next day the people rose early and sacrificed burnt offerings and presented fellowship offerings.(A) Afterward they sat down to eat and drink(B) and got up to indulge in revelry.(C)

Read full chapter