Add parallel Print Page Options

(A)Obìnrin náà sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan. Nígbà tí ó rí í pé ọmọ náà rẹwà, ó gbé ọmọ náà pamọ́ fún oṣù mẹ́ta.

Read full chapter

and she became pregnant and gave birth to a son. When she saw that he was a fine(A) child, she hid him for three months.(B)

Read full chapter

22 (A)Nígbà náà ni Farao pàṣẹ yìí fún gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ pé; “Gbogbo ọmọkùnrin tí a bí ni kí ẹ gbé jù sínú odò Naili, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọbìnrin ni kí ẹ jẹ́ kí wọn ó wà láààyè.”

Read full chapter

22 Then Pharaoh gave this order to all his people: “Every Hebrew boy that is born you must throw into the Nile,(A) but let every girl live.”(B)

Read full chapter