Add parallel Print Page Options

28 Kí ẹni tí ń jalè má ṣe jalè mọ́: ṣùgbọ́n kí ó kúkú máa ṣe làálàá, kí ó máa fi ọwọ́ rẹ̀ ṣiṣẹ́ ohun tí ó dára, kí òun lè ní láti pín fún ẹni tí ó ṣe aláìní.

Read full chapter

28 Anyone who has been stealing must steal no longer, but must work,(A) doing something useful with their own hands,(B) that they may have something to share with those in need.(C)

Read full chapter

10 (A)Nítorí nígbà tí àwa wà lọ́dọ̀ yín, a ṣe àwọn òfin wọ̀nyí fún un yín pé, “Bí ẹnikẹ́ni kò bá fẹ́ ṣiṣẹ́, kí ó má ṣe jẹun.”

11 (B)A gbọ́ pé àwọn kan wà láàrín yín tí wọn jẹ́ ìmẹ́lẹ́. Wọ́n jẹ́ atọjúlékiri. 12 (C)Ǹjẹ́ irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ ni àwa ń pàṣẹ fún, tí a sì ń rọ̀ nínú Jesu Kristi Olúwa pé kí wọn ó máa ṣiṣẹ́ fún oúnjẹ tí wọ́n ń jẹ.

Read full chapter

10 For even when we were with you,(A) we gave you this rule: “The one who is unwilling to work(B) shall not eat.”

11 We hear that some among you are idle and disruptive. They are not busy; they are busybodies.(C) 12 Such people we command and urge in the Lord Jesus Christ(D) to settle down and earn the food they eat.(E)

Read full chapter