Add parallel Print Page Options

(A)Nínú rẹ̀ ni àwa rí ìràpadà gba nípa ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ àti ìdáríjì àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa, ní ìbámu pẹ̀lú ọrọ̀ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run

Read full chapter

In him we have redemption(A) through his blood,(B) the forgiveness of sins, in accordance with the riches(C) of God’s grace

Read full chapter

Pé ni gbogbo ìgbà tí ń bọ̀ kí ó bà á lè fi ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ tí o pọ̀ rékọjá hàn fún wa nínú ìṣeun rẹ̀ sì wà nínú Kristi Jesu.

Read full chapter

in order that in the coming ages he might show the incomparable riches of his grace,(A) expressed in his kindness(B) to us in Christ Jesus.

Read full chapter

19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run mi yóò pèsè ní kíkún fún gbogbo àìní yín, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ̀ nínú ògo nínú Kristi Jesu.

Read full chapter

19 And my God will meet all your needs(A) according to the riches of his glory(B) in Christ Jesus.

Read full chapter

27 Àwọn ẹni tí Ọlọ́run yàn láti fihàn láàrín àwọn aláìkọlà nípa ọ̀rọ̀ ògo ohun ìjìnlẹ̀ yìí, èyí tí í ṣe Kristi ìrètí ògo nínú yín.

Read full chapter

27 To them God has chosen to make known(A) among the Gentiles the glorious riches(B) of this mystery, which is Christ in you,(C) the hope of glory.

Read full chapter