Add parallel Print Page Options

Ìdájọ́ níwájú ẹni ìgbàanì

(A)“Bí mo ṣe ń wò,

“a gbé ìtẹ́ ọba kan kalẹ̀,
    ẹni ìgbàanì jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀,
Aṣọ rẹ̀ funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú;
    irun orí rẹ̀ funfun bí òwú,
ìtẹ́ ọba rẹ̀ rí bí ọwọ́ iná.
    Àwọn kẹ̀kẹ́ rẹ ń jó bí i iná.
10 (B)Odò iná ń sàn,
    ó ń jáde ní iwájú rẹ̀ wá,
Àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún ń ṣe ìránṣẹ́ fún un;
Ọ̀nà ẹgbẹẹgbàárùn-ún nígbà ẹgbàárùn-ún dúró níwájú rẹ̀.
Àwọn onídàájọ́ jókòó,
    a sì ṣí ìwé wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀.

Read full chapter

“As I looked,

“thrones were set in place,
    and the Ancient of Days(A) took his seat.(B)
His clothing was as white as snow;(C)
    the hair of his head was white like wool.(D)
His throne was flaming with fire,
    and its wheels(E) were all ablaze.
10 A river of fire(F) was flowing,
    coming out from before him.(G)
Thousands upon thousands attended him;
    ten thousand times ten thousand stood before him.
The court was seated,
    and the books(H) were opened.

Read full chapter