Amosi 5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Wò mí kí o sì yè
5 Gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ìwọ ilé Israẹli, ìpohùnréré ẹkún tí mo ṣe nípa rẹ:
2 “Wúńdíá Israẹli ṣubú
láì kò sì le padà dìde
ó di ẹni ìkọ̀tì ní ilẹ̀ rẹ̀
kò sí ẹni tí yóò gbé e dìde.”
3 Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí:
“Ìlú tí ẹgbẹ̀rún alágbára ti jáde,
yóò dín ku ọgọ́ọ̀rún ní Israẹli.
Ìlú tí ọgọ́ọ̀rún alàgbà ti jáde
yóò ṣẹ́kù ẹni mẹ́wàá.”
4 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ilé Israẹli:
“Wá mi kí o sì yè;
5 Ẹ má ṣe wá Beteli,
Ẹ má ṣe lọ sí Gilgali
Ẹ má ṣe rìnrìn àjò lọ sí Beerṣeba.
Nítorí dájúdájú a ó kó Gilgali ní ìgbèkùn
A ó sì sọ Beteli di asán.”
6 Ẹ wá Olúwa, ẹ̀yin yóò sì yè,
kí ó má ba à gbilẹ̀ bí iná ní Josẹfu
a sì jó o run
Beteli kò sì ní rí ẹni tí yóò bu omi pa á.
7 Ẹ̀yin tí ẹ̀ sọ òdodo di ìkorò
tí ẹ sì gbé olódodo ṣánlẹ̀.
8 Ẹni tí ó dá ìràwọ̀ Pleiadesi àti Orioni
ẹni tí ó sọ òru dúdú di òwúrọ̀
tí ó sọ ọjọ́ dúdú di ìmọ́lẹ̀
ẹni tí ó wọ́ omi Òkun jọ pọ̀
tí ó sì rọ̀ wọ́n sí orí ilẹ̀
Olúwa ni orúkọ rẹ̀,
9 Ó fọ́n ìparun sí ìlú olódi
tí ó sì sọ àwọn ibùgbé àwọn ọmọ-aládé di ahoro.
10 Ìwọ kórìíra ẹni tí ń bá ni wí ní ẹnu ibodè
ó sì ń pẹ̀gàn ẹni tí ń sọ òtítọ́.
11 Ìwọ ń tẹ tálákà mọ́lẹ̀
o ń fi ipá gba ọkà lọ́wọ́ wọn
Nítorí náà, ìwọ ti fi òkúta tí a gbẹ́ kọ́lé
ṣùgbọ́n ẹ kò sì ní gbé inú wọn
Nítòótọ́ ìwọ ti gbin ọgbà àjàrà tí ó lẹ́wà.
Ìwọ kò ní mu wáìnì inú wọn
12 Nítorí mo mọ iye àìṣedéédéé rẹ
mo sì mọ bí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ tí tóbi tó.
Ìwọ ni olódodo lára, ìwọ sì ń gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀
o sì ń fi òtítọ́ du tálákà ní ilé ẹjọ́
13 Àwọn ọlọ́gbọ́n máa ń dákẹ́ jẹ́ẹ́ ní àkókò wọ̀nyí,
nítorí búburú ni gbogbo ọjọ́.
14 Wá rere, má ṣe wá búburú
kí ìwọ ba à le yè
Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun yóò wà pẹ̀lú rẹ.
Òun yóò sì wà pẹ̀lú rẹ bí ìwọ ṣe wí
15 Kórìíra búburú kí o sì fẹ́ rere
dúró ní orí òtítọ́ ní ilé ẹjọ́
bóyá Olúwa Ọlọ́run alágbára
yóò ṣíjú àánú wo ọmọ Josẹfu tó ṣẹ́kù.
16 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí:
“Ẹkún yóò wà ní àwọn òpópónà
igbe ìnira yóò sì wà ní àwọn gbàgede ìlú
A ó kó àwọn àgbẹ̀ jọ láti sọkún
àti àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ láti pohùnréré ẹkún
17 Ìpohùnréré ẹkún yóò wà ní gbogbo ọgbà àjàrà
Nítorí èmi yóò la àárín yín kọjá,”
ni Olúwa wí.
Ọjọ́ Olúwa
18 Ègbé ni fún ìwọ tí ó pẹ́
nítorí ọjọ́ Olúwa
kí ni ìwọ fi pẹ́ fún ọjọ́ Olúwa?
Ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn ní ojú ọjọ́
19 Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ó sá fún kìnnìún,
tí ó padà wá bọ́ sí ẹnu àmọ̀tẹ́kùn.
Yóò dàbí ẹni tí ó wọ ilé rẹ̀ lọ
tí ó sinmi lé ògiri ilé rẹ̀
tí ejò sì bù ú ṣán.
20 Ǹjẹ́ ọjọ́ Olúwa kò ha ní ṣókùnkùn dípò kí ó ní ìmọ́lẹ̀?
Tí yóò sì ṣókùnkùn dúdú láìsí ìmọ́lẹ̀ kankan níbẹ̀.
21 “Mo kórìíra, mo kẹ́gàn àwọn àsè ẹ̀sìn in yín
Èmi kò sì ní inú dídùn sí àpéjọ yín
22 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ mú ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà wá
Èmi kò ní tẹ́wọ́ gbà wọ́n
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ mú àṣàyàn ọrẹ àlàáfíà wá.
Èmi kò ní náání wọn.
23 Ẹ gbé ariwo orin yín sẹ́yìn
Èmi kò ní fetísí ohun èlò orin yín.
24 Jẹ́ kí òtítọ́ sàn bí odò
àti òdodo bí ìsun tí kò lé è gbẹ!
25 (A)“Àbí ẹ̀yin mú ẹbọ àti ọrẹ tọ̀ mí wá
ní ogójì ọdún ní aginjù ìwọ ilé Israẹli?
26 Ẹ̀yin ti gbé ibi ìrúbọ àwọn ọba yín sókè
ibùgbé àwọn òrìṣà yín
àní, ti àwọn òrìṣà yín tí ó níyì jùlọ,
èyí tí ẹ̀yin fi ọwọ́ ara yín ṣe.
27 Nítorí náà èmi yóò rán an yín lọ sí ìgbèkùn ní ìkọjá Damasku,”
ni Olúwa wí, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ọlọ́run alágbára.
Amos 5
New International Version
A Lament and Call to Repentance
5 Hear this word, Israel, this lament(A) I take up concerning you:
2 “Fallen is Virgin(B) Israel,
never to rise again,
deserted in her own land,
with no one to lift her up.(C)”
3 This is what the Sovereign Lord says to Israel:
“Your city that marches out a thousand strong
will have only a hundred left;
your town that marches out a hundred strong
will have only ten left.(D)”
4 This is what the Lord says to Israel:
“Seek(E) me and live;(F)
5 do not seek Bethel,
do not go to Gilgal,(G)
do not journey to Beersheba.(H)
For Gilgal will surely go into exile,
and Bethel will be reduced to nothing.[a](I)”
6 Seek(J) the Lord and live,(K)
or he will sweep through the tribes of Joseph like a fire;(L)
it will devour them,
and Bethel(M) will have no one to quench it.(N)
8 He who made the Pleiades and Orion,(R)
who turns midnight into dawn(S)
and darkens day into night,(T)
who calls for the waters of the sea
and pours them out over the face of the land—
the Lord is his name.(U)
9 With a blinding flash he destroys the stronghold
and brings the fortified city to ruin.(V)
10 There are those who hate the one who upholds justice in court(W)
and detest the one who tells the truth.(X)
11 You levy a straw tax on the poor(Y)
and impose a tax on their grain.
Therefore, though you have built stone mansions,(Z)
you will not live in them;(AA)
though you have planted lush vineyards,
you will not drink their wine.(AB)
12 For I know how many are your offenses
and how great your sins.(AC)
There are those who oppress the innocent and take bribes(AD)
and deprive the poor(AE) of justice in the courts.(AF)
13 Therefore the prudent keep quiet(AG) in such times,
for the times are evil.(AH)
14 Seek good, not evil,
that you may live.(AI)
Then the Lord God Almighty will be with you,
just as you say he is.
15 Hate evil,(AJ) love good;(AK)
maintain justice in the courts.(AL)
Perhaps(AM) the Lord God Almighty will have mercy(AN)
on the remnant(AO) of Joseph.
16 Therefore this is what the Lord, the Lord God Almighty, says:
“There will be wailing(AP) in all the streets(AQ)
and cries of anguish in every public square.
The farmers(AR) will be summoned to weep
and the mourners to wail.
17 There will be wailing(AS) in all the vineyards,
for I will pass through(AT) your midst,”
says the Lord.(AU)
The Day of the Lord
18 Woe to you who long
for the day of the Lord!(AV)
Why do you long for the day of the Lord?(AW)
That day will be darkness,(AX) not light.(AY)
19 It will be as though a man fled from a lion
only to meet a bear,(AZ)
as though he entered his house
and rested his hand on the wall
only to have a snake bite him.(BA)
20 Will not the day of the Lord be darkness,(BB) not light—
pitch-dark, without a ray of brightness?(BC)
21 “I hate,(BD) I despise your religious festivals;(BE)
your assemblies(BF) are a stench to me.
22 Even though you bring me burnt offerings(BG) and grain offerings,
I will not accept them.(BH)
Though you bring choice fellowship offerings,
I will have no regard for them.(BI)
23 Away with the noise of your songs!
I will not listen to the music of your harps.(BJ)
24 But let justice(BK) roll on like a river,
righteousness(BL) like a never-failing stream!(BM)
25 “Did you bring me sacrifices(BN) and offerings
forty years(BO) in the wilderness, people of Israel?
26 You have lifted up the shrine of your king,
the pedestal of your idols,(BP)
the star of your god[b]—
which you made for yourselves.
27 Therefore I will send you into exile(BQ) beyond Damascus,”
says the Lord, whose name is God Almighty.(BR)
Amosi 5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Wò mí kí o sì yè
5 Gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ìwọ ilé Israẹli, ìpohùnréré ẹkún tí mo ṣe nípa rẹ:
2 “Wúńdíá Israẹli ṣubú
láì kò sì le padà dìde
ó di ẹni ìkọ̀tì ní ilẹ̀ rẹ̀
kò sí ẹni tí yóò gbé e dìde.”
3 Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí:
“Ìlú tí ẹgbẹ̀rún alágbára ti jáde,
yóò dín ku ọgọ́ọ̀rún ní Israẹli.
Ìlú tí ọgọ́ọ̀rún alàgbà ti jáde
yóò ṣẹ́kù ẹni mẹ́wàá.”
4 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ilé Israẹli:
“Wá mi kí o sì yè;
5 Ẹ má ṣe wá Beteli,
Ẹ má ṣe lọ sí Gilgali
Ẹ má ṣe rìnrìn àjò lọ sí Beerṣeba.
Nítorí dájúdájú a ó kó Gilgali ní ìgbèkùn
A ó sì sọ Beteli di asán.”
6 Ẹ wá Olúwa, ẹ̀yin yóò sì yè,
kí ó má ba à gbilẹ̀ bí iná ní Josẹfu
a sì jó o run
Beteli kò sì ní rí ẹni tí yóò bu omi pa á.
7 Ẹ̀yin tí ẹ̀ sọ òdodo di ìkorò
tí ẹ sì gbé olódodo ṣánlẹ̀.
8 Ẹni tí ó dá ìràwọ̀ Pleiadesi àti Orioni
ẹni tí ó sọ òru dúdú di òwúrọ̀
tí ó sọ ọjọ́ dúdú di ìmọ́lẹ̀
ẹni tí ó wọ́ omi Òkun jọ pọ̀
tí ó sì rọ̀ wọ́n sí orí ilẹ̀
Olúwa ni orúkọ rẹ̀,
9 Ó fọ́n ìparun sí ìlú olódi
tí ó sì sọ àwọn ibùgbé àwọn ọmọ-aládé di ahoro.
10 Ìwọ kórìíra ẹni tí ń bá ni wí ní ẹnu ibodè
ó sì ń pẹ̀gàn ẹni tí ń sọ òtítọ́.
11 Ìwọ ń tẹ tálákà mọ́lẹ̀
o ń fi ipá gba ọkà lọ́wọ́ wọn
Nítorí náà, ìwọ ti fi òkúta tí a gbẹ́ kọ́lé
ṣùgbọ́n ẹ kò sì ní gbé inú wọn
Nítòótọ́ ìwọ ti gbin ọgbà àjàrà tí ó lẹ́wà.
Ìwọ kò ní mu wáìnì inú wọn
12 Nítorí mo mọ iye àìṣedéédéé rẹ
mo sì mọ bí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ tí tóbi tó.
Ìwọ ni olódodo lára, ìwọ sì ń gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀
o sì ń fi òtítọ́ du tálákà ní ilé ẹjọ́
13 Àwọn ọlọ́gbọ́n máa ń dákẹ́ jẹ́ẹ́ ní àkókò wọ̀nyí,
nítorí búburú ni gbogbo ọjọ́.
14 Wá rere, má ṣe wá búburú
kí ìwọ ba à le yè
Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun yóò wà pẹ̀lú rẹ.
Òun yóò sì wà pẹ̀lú rẹ bí ìwọ ṣe wí
15 Kórìíra búburú kí o sì fẹ́ rere
dúró ní orí òtítọ́ ní ilé ẹjọ́
bóyá Olúwa Ọlọ́run alágbára
yóò ṣíjú àánú wo ọmọ Josẹfu tó ṣẹ́kù.
16 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí:
“Ẹkún yóò wà ní àwọn òpópónà
igbe ìnira yóò sì wà ní àwọn gbàgede ìlú
A ó kó àwọn àgbẹ̀ jọ láti sọkún
àti àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ láti pohùnréré ẹkún
17 Ìpohùnréré ẹkún yóò wà ní gbogbo ọgbà àjàrà
Nítorí èmi yóò la àárín yín kọjá,”
ni Olúwa wí.
Ọjọ́ Olúwa
18 Ègbé ni fún ìwọ tí ó pẹ́
nítorí ọjọ́ Olúwa
kí ni ìwọ fi pẹ́ fún ọjọ́ Olúwa?
Ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn ní ojú ọjọ́
19 Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ó sá fún kìnnìún,
tí ó padà wá bọ́ sí ẹnu àmọ̀tẹ́kùn.
Yóò dàbí ẹni tí ó wọ ilé rẹ̀ lọ
tí ó sinmi lé ògiri ilé rẹ̀
tí ejò sì bù ú ṣán.
20 Ǹjẹ́ ọjọ́ Olúwa kò ha ní ṣókùnkùn dípò kí ó ní ìmọ́lẹ̀?
Tí yóò sì ṣókùnkùn dúdú láìsí ìmọ́lẹ̀ kankan níbẹ̀.
21 “Mo kórìíra, mo kẹ́gàn àwọn àsè ẹ̀sìn in yín
Èmi kò sì ní inú dídùn sí àpéjọ yín
22 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ mú ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà wá
Èmi kò ní tẹ́wọ́ gbà wọ́n
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ mú àṣàyàn ọrẹ àlàáfíà wá.
Èmi kò ní náání wọn.
23 Ẹ gbé ariwo orin yín sẹ́yìn
Èmi kò ní fetísí ohun èlò orin yín.
24 Jẹ́ kí òtítọ́ sàn bí odò
àti òdodo bí ìsun tí kò lé è gbẹ!
25 (A)“Àbí ẹ̀yin mú ẹbọ àti ọrẹ tọ̀ mí wá
ní ogójì ọdún ní aginjù ìwọ ilé Israẹli?
26 Ẹ̀yin ti gbé ibi ìrúbọ àwọn ọba yín sókè
ibùgbé àwọn òrìṣà yín
àní, ti àwọn òrìṣà yín tí ó níyì jùlọ,
èyí tí ẹ̀yin fi ọwọ́ ara yín ṣe.
27 Nítorí náà èmi yóò rán an yín lọ sí ìgbèkùn ní ìkọjá Damasku,”
ni Olúwa wí, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ọlọ́run alágbára.
Amos 5
New International Version
A Lament and Call to Repentance
5 Hear this word, Israel, this lament(A) I take up concerning you:
2 “Fallen is Virgin(B) Israel,
never to rise again,
deserted in her own land,
with no one to lift her up.(C)”
3 This is what the Sovereign Lord says to Israel:
“Your city that marches out a thousand strong
will have only a hundred left;
your town that marches out a hundred strong
will have only ten left.(D)”
4 This is what the Lord says to Israel:
“Seek(E) me and live;(F)
5 do not seek Bethel,
do not go to Gilgal,(G)
do not journey to Beersheba.(H)
For Gilgal will surely go into exile,
and Bethel will be reduced to nothing.[a](I)”
6 Seek(J) the Lord and live,(K)
or he will sweep through the tribes of Joseph like a fire;(L)
it will devour them,
and Bethel(M) will have no one to quench it.(N)
8 He who made the Pleiades and Orion,(R)
who turns midnight into dawn(S)
and darkens day into night,(T)
who calls for the waters of the sea
and pours them out over the face of the land—
the Lord is his name.(U)
9 With a blinding flash he destroys the stronghold
and brings the fortified city to ruin.(V)
10 There are those who hate the one who upholds justice in court(W)
and detest the one who tells the truth.(X)
11 You levy a straw tax on the poor(Y)
and impose a tax on their grain.
Therefore, though you have built stone mansions,(Z)
you will not live in them;(AA)
though you have planted lush vineyards,
you will not drink their wine.(AB)
12 For I know how many are your offenses
and how great your sins.(AC)
There are those who oppress the innocent and take bribes(AD)
and deprive the poor(AE) of justice in the courts.(AF)
13 Therefore the prudent keep quiet(AG) in such times,
for the times are evil.(AH)
14 Seek good, not evil,
that you may live.(AI)
Then the Lord God Almighty will be with you,
just as you say he is.
15 Hate evil,(AJ) love good;(AK)
maintain justice in the courts.(AL)
Perhaps(AM) the Lord God Almighty will have mercy(AN)
on the remnant(AO) of Joseph.
16 Therefore this is what the Lord, the Lord God Almighty, says:
“There will be wailing(AP) in all the streets(AQ)
and cries of anguish in every public square.
The farmers(AR) will be summoned to weep
and the mourners to wail.
17 There will be wailing(AS) in all the vineyards,
for I will pass through(AT) your midst,”
says the Lord.(AU)
The Day of the Lord
18 Woe to you who long
for the day of the Lord!(AV)
Why do you long for the day of the Lord?(AW)
That day will be darkness,(AX) not light.(AY)
19 It will be as though a man fled from a lion
only to meet a bear,(AZ)
as though he entered his house
and rested his hand on the wall
only to have a snake bite him.(BA)
20 Will not the day of the Lord be darkness,(BB) not light—
pitch-dark, without a ray of brightness?(BC)
21 “I hate,(BD) I despise your religious festivals;(BE)
your assemblies(BF) are a stench to me.
22 Even though you bring me burnt offerings(BG) and grain offerings,
I will not accept them.(BH)
Though you bring choice fellowship offerings,
I will have no regard for them.(BI)
23 Away with the noise of your songs!
I will not listen to the music of your harps.(BJ)
24 But let justice(BK) roll on like a river,
righteousness(BL) like a never-failing stream!(BM)
25 “Did you bring me sacrifices(BN) and offerings
forty years(BO) in the wilderness, people of Israel?
26 You have lifted up the shrine of your king,
the pedestal of your idols,(BP)
the star of your god[b]—
which you made for yourselves.
27 Therefore I will send you into exile(BQ) beyond Damascus,”
says the Lord, whose name is God Almighty.(BR)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.
Holy Bible, New International Version®, NIV® Copyright ©1973, 1978, 1984, 2011 by Biblica, Inc.® Used by permission. All rights reserved worldwide.
NIV Reverse Interlinear Bible: English to Hebrew and English to Greek. Copyright © 2019 by Zondervan.