Add parallel Print Page Options

Òun yóò sì fi ìtura fún ẹ̀yin tí a ti pọ́n lójú àti fún àwa náà pẹ̀lú. Èyí yóò sì ṣe nígbà ìfarahàn Jesu Olúwa láti ọ̀run wá fún wá nínú ọwọ́ iná pẹ̀lú àwọn angẹli alágbára. (A)Òun yóò fi ìyà jẹ àwọn tí kò mọ Ọlọ́run àti àwọn tí ń ṣe àìgbọ́ràn sí ìhìnrere Jesu Olúwa wa. A ó fi ìparun àìnípẹ̀kun jẹ wọ́n ní yà, a ó sì ṣe wọn mọ̀ kúrò níwájú Olúwa àti inú ògo agbára rẹ̀ 10 Ní ọjọ́ tí yóò jẹ́ ẹni tí a ó yìn lógo nínú àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ àti ẹni àwòyanu ní àárín gbogbo àwọn tí ó ti gbàgbọ́. Èyí kò yọ yín sílẹ̀, nítorí ẹ ti gba ẹ̀rí tí a jẹ́ sí yín gbọ́.

Read full chapter

and give relief to you who are troubled, and to us as well. This will happen when the Lord Jesus is revealed from heaven(A) in blazing fire(B) with his powerful angels.(C) He will punish(D) those who do not know God(E) and do not obey the gospel of our Lord Jesus.(F) They will be punished with everlasting destruction(G) and shut out from the presence of the Lord(H) and from the glory of his might(I) 10 on the day(J) he comes to be glorified(K) in his holy people and to be marveled at among all those who have believed. This includes you, because you believed our testimony to you.(L)

Read full chapter