Add parallel Print Page Options

Ẹni tí ó mú wa yẹ bí ìránṣẹ́ májẹ̀mú tuntun; kì í ṣe ní ti ìwé àkọsílẹ̀ ṣùgbọ́n ní ti ẹ̀mí, nítorí ìwé a máa pa ni, ṣùgbọ́n ẹ̀mí a máa sọ ní di ààyè.

Read full chapter

He has made us competent as ministers of a new covenant(A)—not of the letter(B) but of the Spirit; for the letter kills, but the Spirit gives life.(C)

Read full chapter

68 (A)Nígbà náà ni Simoni Peteru dá a lóhùn pé, “Olúwa, ọ̀dọ̀ ta ni àwa ó lọ? Ìwọ ni ó ni ọ̀rọ̀ ìyè àìnípẹ̀kun.

Read full chapter

68 Simon Peter answered him,(A) “Lord, to whom shall we go? You have the words of eternal life.(B)

Read full chapter