Add parallel Print Page Options

Nítorí náà, ẹ fi àrankàn gbogbo sílẹ̀ ni apá kan, àti ẹ̀tàn gbogbo, àti àgàbàgebè, àti ìlara, àti sísọ ọ̀rọ̀ búburú gbogbo. Bí ọmọ ọwọ́ tuntun, kí ẹ máa fẹ́ wàrà ti Ẹ̀mí, èyí tí kò lẹ́tàn, kí ẹ̀yin lè máa tipasẹ̀ rẹ̀ dàgbà sí ìgbàlà, (A)nísinsin yìí tí ẹ̀yin ti tọ́ ọ wò pé rere ni Olúwa.

Àpáta iyè àti ènìyàn tí a yàn

(B)Ẹni tí ẹ̀yin ń tọ̀ bọ̀, sí bi òkúta ààyè náà, èyí ti a ti ọwọ́ ènìyàn kọ̀ sílẹ̀ nítòótọ́, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ Ọlọ́run, àṣàyàn òkúta iyebíye. Ẹ̀yin pẹ̀lú, bí òkúta ààyè, ni a kọ́ ní ilé ẹ̀mí, àlùfáà mímọ́, láti máa rú ẹbọ ẹ̀mí, tí i ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọ́run nípa Jesu Kristi. (C)Nítorí nínú Ìwé Mímọ́, ó wí pe:

“Kíyèsi i, mo fi pàtàkì òkúta igun ilé àṣàyàn,
    iyebíye, lélẹ̀ ni Sioni:
ẹni tí ó bá sì gbà á gbọ́
    ojú kì yóò tì í.”

(D)Báyìí fún ẹ̀yin ti ẹ gbà á gbọ́, ó ṣe iyebíye; ṣùgbọ́n fún àwọn tí kò gbà á gbọ́,

“Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀sílẹ̀,
    òun ni ó di pàtàkì igun ilé,”

(E)àti pẹ̀lú,

“Òkúta ìdìgbòlù,
    àti àpáta ìkọ̀sẹ̀.”

Nítorí wọ́n kọsẹ̀ nípa ṣíṣe àìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀ náà, sínú èyí tí a gbé yàn wọ́n sí pẹ̀lú.

(F)Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ni ìran tí a yàn olú àlùfáà, Orílẹ̀-èdè mímọ́, Ènìyàn ọ̀tọ̀ ki ẹ̀yin lè fi ọláńlá ẹni tí ó pè yín jáde kúrò nínú òkùnkùn sínú ìmọ́lẹ̀ ìyanu rẹ̀ hàn: 10 (G)Ẹ̀yin tí kì í ṣe ènìyàn nígbà kan rí, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ẹ̀yin ti di ènìyàn Ọlọ́run, ẹ̀yin tí kò rí àánú gbà rí, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ẹ ti rí àánú gbà.

11 Olùfẹ́ ọ̀wọ́n, mo bẹ̀ yín, bí àjèjì àti àtìpó, láti fà sẹ́hìn kúrò nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara, tí ń ba ọkàn jagun; 12 Kí ìwà yín láàrín àwọn aláìkọlà dára; pé, bí wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ yín bí olùṣe búburú, nípa iṣẹ́ rere yín tí wọn ó máa kíyèsi, kí wọ́n lè máa yin Ọlọ́run lógo lọ́jọ́ ti òun ba bẹ̀ wá wò.

Ìbọ̀wọ̀ fún àwọn òfin àti àwọn aláṣẹ

13 Ẹ máa tẹríba fún gbogbo ìlànà ènìyàn nítorí ti Olúwa: ìbá à ṣe fún ọba tàbí fún olórí. 14 Tàbí fún àwọn baálẹ̀, fún àwọn tí a rán láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti gbẹ̀san lára àwọn tí ń ṣe búburú, àti fún ìyìn àwọn tí ń ṣe rere. 15 Ìfẹ́ Ọlọ́run sá ni èyí pé, ní rere í ṣe, kí ẹ lè dẹ́kun ọ̀rọ̀ àìmọ̀kan òmùgọ̀ ènìyàn. 16 Ẹ máa gbé gẹ́gẹ́ bí ẹni òmìnira, ṣùgbọ́n ẹ ma ṣe lo òmìnira yín láti bo ibi mọ́lẹ̀; ṣùgbọ́n kí ẹ gbé gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ Ọlọ́run. 17 Ẹ bọ̀wọ̀ fún gbogbo ènìyàn, ẹ fẹ́ àwọn ará, ẹ bẹ̀rù Ọlọ́run, ẹ bọ̀wọ̀ fún ọba.

18 Ẹ̀yin ọmọ ọ̀dọ̀, ẹ máa tẹríba fún àwọn ọ̀gá yín pẹ̀lú ìbẹ̀rù gbogbo, kì í ṣe fún àwọn ẹni rere àti oníwà tútù nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn òǹrorò pẹ̀lú. 19 Nítorí pé èyí ní ìgbóríyìn fún, bí ènìyàn bá fi ara da ìrora, ìjìyà lọ́nà àìtọ́, nítorí ọkàn rere sí Ọlọ́run. 20 Ṣùgbọ́n ògo kín ni ó jẹ́, nígbà tí ẹ ba ṣẹ̀ tí a sì lù yín, bí ẹ bá fi sùúrù gbà á? Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yin bá ń ṣe rere tí ẹ sì ń jìyà, bí ẹ bá fi sùúrù gbà á, ẹ̀yín ní ọpẹ́ lọ́dọ̀ Ọlọ́run. 21 Sí èyí ni a pè yín: nítorí Kristi pẹ̀lú jìyà fún un yin, ó fi àpẹẹrẹ sílẹ̀ fún un yín, kí ẹ̀yin lè máa tọ ipasẹ̀ rẹ̀:

22 (H)“Òun kò dẹ́ṣẹ̀ kankan,
    bẹ́ẹ̀ sì ni, a kò rí ẹ̀tàn kan lẹ́nu rẹ̀.”

23 Ẹni, nígbà tí a kẹ́gàn rẹ̀, tí kò sì padà kẹ́gàn; nígbà tí ó jìyà tí kò sì halẹ̀; ṣùgbọ́n ó fi ọ̀ràn rẹ̀ lé ẹni ti ń ṣe ìdájọ́ òdodo lọ́wọ́. 24 (I)Ẹni tí òun tìkára rẹ̀ fi ara rẹ̀ ru ẹ̀ṣẹ̀ wa lórí igi àgbélébùú, pé kí àwa lè di òkú sí ẹ̀ṣẹ̀, ki a sì di ààyè sí òdodo: nípa ìjìyà ẹni tí ó mú yín láradá. 25 Nítorí tí ẹ̀yin ń ṣáko lọ bí àgùntàn, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ẹ̀yin ti padà sí ọ̀dọ̀ olùṣọ́-àgùntàn àti bíṣọ́ọ̀bù ọkàn yín.

Chosen as Living Stones

Therefore, ridding yourselves of all malice and all deceit and hypocrisy and envy and all slander, like newborn infants long for the unadulterated spiritual milk, so that by it you may grow up to salvation, if you have tasted that the Lord is kind,[a] to whom you are drawing near, a living stone rejected by men but chosen and precious in the sight of God. And you yourselves, as living stones, are being built up as a spiritual house for a holy priesthood, to offer up spiritual sacrifices acceptable to God through Jesus Christ. For it stands in scripture,

“Behold, I am laying in Zion a stone, a chosen and precious cornerstone,
and the one who believes in him will never be put to shame.”[b]

Therefore the honor is for you who believe, but for those who refuse to believe,

“The stone that the builders rejected,
this one has become the cornerstone[c],”

and

“A stone of stumbling and a rock of offense,”[d]

who stumble because they[e] disobey the word to which also they were consigned. But you are a chosen race,[f] a royal priesthood, a holy nation, a people for God’s possession, so that you may proclaim the virtues of the one who called you out of darkness into his marvelous light, 10 who once were not a people, but now are the people of God, the ones who were not shown mercy, but now are shown mercy.[g]

11 Dear friends, I urge you as foreigners and temporary residents to abstain from fleshly desires which wage war against your[h] soul, 12 maintaining your good conduct among the Gentiles, so that in the things in which they slander you as evildoers, by seeing your good deeds they may glorify God on the day of visitation.

Submission to Established Authority

13 Subject yourselves to every human authority for the sake of the Lord, whether to a king[i] as having supreme authority, 14 or to governors as those sent out by him for the punishment of those who do evil and the praise of those who do good. 15 For the will of God is as follows: by[j] doing good to silence the ignorance of foolish people. 16 Live as free persons, and not using your[k] freedom as a covering for evil, but as slaves of God. 17 Honor all people, love the community of believers, fear God, honor the king.[l]

18 Domestic slaves, be subject to your[m] masters with all respect, not only to those who are good and gentle, but also to those who are unjust. 19 For this finds favor, if because of consciousness of God someone endures sorrows while[n] suffering unjustly. 20 For what credit is it if, when you[o] sin and are beaten for it, you endure? But if you endure when you[p] do good and suffer for it, this finds favor with God. 21 For to this you were called, because Christ also suffered for you, leaving you an example, so that you should follow in his footsteps, 22 who did not commit sin, nor was deceit found in his mouth,[q] 23 who when he[r] was reviled, did not revile in return; when[s] suffering, he did not threaten, but entrusted himself to the one who judges justly, 24 who himself bore our sins in his body on the tree, so that we may die to sins and live to righteousness, by whose wounds you were healed. 25 For you were going astray like sheep, but you have turned back now to the shepherd and guardian of your souls.

Footnotes

  1. 1 Peter 2:3 A quotation from Ps 34:8
  2. 1 Peter 2:6 A quotation from Isa 28:16
  3. 1 Peter 2:7 Literally “into the head of the corner”
  4. 1 Peter 2:8 A quotation from Isa 8:14
  5. 1 Peter 2:8 Here “because” is supplied as a component of the participle (“disobey”) which is understood as causal
  6. 1 Peter 2:9 Or “people,” or “generation,” or “nation”
  7. 1 Peter 2:10 This verse contains quotations from Hos 1:6, 9; 2:23
  8. 1 Peter 2:11 Literally “the”; the Greek article is used here as a possessive pronoun
  9. 1 Peter 2:13 Or “to the emperor”
  10. 1 Peter 2:15 Here “by” is supplied as a component of the participle (“doing good”) which is understood as means
  11. 1 Peter 2:16 Literally “the”; the Greek article is used here as a possessive pronoun
  12. 1 Peter 2:17 Or “the emperor”
  13. 1 Peter 2:18 Literally “the”; the Greek article is used here as a possessive pronoun
  14. 1 Peter 2:19 Here “while” is supplied as a component of the participle (“suffering”) which is understood as temporal
  15. 1 Peter 2:20 Here “when” is supplied as a component of the participle (“sin”) which is understood as temporal
  16. 1 Peter 2:20 Here “when” is supplied as a component of the participle (“do good”) which is understood as temporal
  17. 1 Peter 2:22 This verse contains quotations from Isa 53:9
  18. 1 Peter 2:23 Here “when” is supplied as a component of the participle (“was reviled”) which is understood as temporal
  19. 1 Peter 2:23 Here “when” is supplied as a component of the participle (“suffering”) which is understood as temporal

Wherefore laying aside all malice, and all guile, and hypocrisies, and envies, and all evil speakings,

As newborn babes, desire the sincere milk of the word, that ye may grow thereby:

If so be ye have tasted that the Lord is gracious.

To whom coming, as unto a living stone, disallowed indeed of men, but chosen of God, and precious,

Ye also, as lively stones, are built up a spiritual house, an holy priesthood, to offer up spiritual sacrifices, acceptable to God by Jesus Christ.

Wherefore also it is contained in the scripture, Behold, I lay in Sion a chief corner stone, elect, precious: and he that believeth on him shall not be confounded.

Unto you therefore which believe he is precious: but unto them which be disobedient, the stone which the builders disallowed, the same is made the head of the corner,

And a stone of stumbling, and a rock of offence, even to them which stumble at the word, being disobedient: whereunto also they were appointed.

But ye are a chosen generation, a royal priesthood, an holy nation, a peculiar people; that ye should shew forth the praises of him who hath called you out of darkness into his marvellous light;

10 Which in time past were not a people, but are now the people of God: which had not obtained mercy, but now have obtained mercy.

11 Dearly beloved, I beseech you as strangers and pilgrims, abstain from fleshly lusts, which war against the soul;

12 Having your conversation honest among the Gentiles: that, whereas they speak against you as evildoers, they may by your good works, which they shall behold, glorify God in the day of visitation.

13 Submit yourselves to every ordinance of man for the Lord's sake: whether it be to the king, as supreme;

14 Or unto governors, as unto them that are sent by him for the punishment of evildoers, and for the praise of them that do well.

15 For so is the will of God, that with well doing ye may put to silence the ignorance of foolish men:

16 As free, and not using your liberty for a cloke of maliciousness, but as the servants of God.

17 Honour all men. Love the brotherhood. Fear God. Honour the king.

18 Servants, be subject to your masters with all fear; not only to the good and gentle, but also to the froward.

19 For this is thankworthy, if a man for conscience toward God endure grief, suffering wrongfully.

20 For what glory is it, if, when ye be buffeted for your faults, ye shall take it patiently? but if, when ye do well, and suffer for it, ye take it patiently, this is acceptable with God.

21 For even hereunto were ye called: because Christ also suffered for us, leaving us an example, that ye should follow his steps:

22 Who did no sin, neither was guile found in his mouth:

23 Who, when he was reviled, reviled not again; when he suffered, he threatened not; but committed himself to him that judgeth righteously:

24 Who his own self bare our sins in his own body on the tree, that we, being dead to sins, should live unto righteousness: by whose stripes ye were healed.

25 For ye were as sheep going astray; but are now returned unto the Shepherd and Bishop of your souls.