Add parallel Print Page Options

Rubeni

(A)Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Reubeni, àkọ́bí Israẹli. (Nítorí òun ni àkọ́bí; ṣùgbọ́n, bí ó ti ṣe pé ó ba ibùsùn baba rẹ̀ jẹ́, a fi ogún ìbí rẹ̀ fún àwọn ọmọ Josẹfu ọmọ Israẹli: a kì yóò sì ka ìtàn ìdílé náà gẹ́gẹ́ bí ipò ìbí. Nítorí Juda borí àwọn arákùnrin rẹ̀, àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni aláṣẹ ti ń jáde wá; ṣùgbọ́n ogún ìbí jẹ́ ti Josẹfu), àwọn ọmọ Reubeni àkọ́bí Israẹli ni:

Hanoku àti Pallu, Hesroni àti Karmi.

Àwọn ọmọ Joeli:

Ṣemaiah ọmọ rẹ̀, Gogu ọmọ rẹ̀,

Ṣimei ọmọ rẹ̀. Mika ọmọ rẹ̀,

Reaiah ọmọ rẹ̀, Baali ọmọ rẹ̀.

Beera ọmọ rẹ̀, tí Tiglat-Pileseri ọba Asiria kó ní ìgbèkùn lọ. Ìjòyè àwọn ọmọ Reubeni ni Beera jẹ́.

Àti àwọn arákùnrin rẹ̀ nípa ìdílé wọn, nígbà tí a ń ka ìtàn ìdílé ìran wọn:

Jeieli àti Sekariah ni olórí, àti Bela ọmọ Asasi ọmọ Ṣema, ọmọ Joeli.

Wọ́n tí ń gbé Aroeri àní títí dé Nebo àti Baali-Meoni. Àti níhà àríwá, o tẹ̀dó lọ títí dé àtiwọ aginjù láti odò Eufurate; nítorí tí ẹran ọ̀sìn wọn pọ̀ sí i ní ilẹ̀ Gileadi.

10 Àti ní ọjọ́ Saulu, wọ́n bá àwọn ọmọ Hagari jagun, ẹni tí ó ṣubú nípa ọwọ́ wọn; wọ́n sì ń gbé inú àgọ́ wọn ní gbogbo ilẹ̀ àríwá Gileadi.

Ìdílé Gadi

11 Àti àwọn ọmọ Gadi ń gbé lékè wọn, ní ilẹ̀ Baṣani títí dé Saleka:

12 Joeli jẹ́ olórí, Ṣafamu ìran ọmọ, Janai, àti Ṣafati ni Baṣani,

13 Àti àwọn arákùnrin wọn ti ilẹ̀ àwọn baba wọn ní:

Mikaeli, Meṣullamu Ṣeba, Jorai, Jaka, Sia àti Eberi méje.

14 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Abihaili, ọmọ Huri, ọmọ Jeroa, ọmọ Gileadi, ọmọ Mikaeli, ọmọ Jeṣiṣai, ọmọ Jado ọmọ Busi.

15 Ahi, ọmọ Adbeeli, ọmọ Guni, olórí ilé àwọn baba wọn.

16 Wọ́n sì ń gbé Gileadi ní Baṣani àti nínú àwọn ìlú rẹ̀, àti nínú gbogbo ìgbèríko Ṣaroni, ní agbègbè wọn.

17 Gbogbo wọ̀nyí ni a kà nípa ìtàn ìdílé, ní ọjọ́ Jotamu ọba Juda, àti ní ọjọ́ Jeroboamu ọba Israẹli.

18 Àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase, nínú àwọn ọkùnrin alágbára tí wọ́n ń gbé asà àti idà, tí wọ́n sì ń fi ọrun tafà, tí wọ́n sì mòye ogun, jẹ́ ọ̀kẹ́ méjì ènìyàn ó lé ẹgbẹ̀rìnlélógún dín ogójì, tí ó jáde lọ sí ogún náà. 19 Wọ́n sì bá àwọn ọmọ Hagari jagun, pẹ̀lú Jeturi, àti Nafiṣi àti Nadabu. 20 Nígbà tí wọ́n sì rí ìrànlọ́wọ́ gbà si, a sì fi àwọn ọmọ Hagari lé wọn lọ́wọ́, àti gbogbo àwọn tí ó wà pẹ̀lú wọn; nítorí tiwọn ké pe Ọlọ́run ní ogun náà, òun sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wọn; nítorí tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ wọn lé e. 21 Wọ́n sì kó ẹran ọ̀sìn wọn lọ; ìbákasẹ ẹgbàá-mẹ́dọ́gbọ̀n àti àgùntàn ọ̀kẹ́ méjìlá ó lé ẹgbàárùn-ún, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbàá, àti ènìyàn ọ̀kẹ́ márùn-ún. 22 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ṣubú tí a pa, nítorí láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ogun náà, wọ́n sì jókòó ní ipò wọn títí di ìgbà ìkólọ sí ìgbèkùn.

Ààbọ̀ Ẹ̀yà Manase

23 Àwọn ọmọkùnrin ààbọ̀ ẹ̀yà Manase ń gbé ní ilẹ̀ náà: wọ́n bí sí i láti Baṣani títí dé Baali-Hermoni, àti Seniri àti títí dé òkè Hermoni.

24 Wọ̀nyí sì ni àwọn olórí ilé àwọn baba wọn. Eferi, Iṣi, Elieli, Asrieli, Jeremiah, Hodafiah àti Jahdieli àwọn alágbára akọni ọkùnrin, ọkùnrin olókìkí, àti olórí ilé àwọn baba wọn. 25 Wọ́n sì ṣẹ̀ sí Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n sì ṣe àgbèrè tọ àwọn ọlọ́run ènìyàn ilẹ̀ náà lẹ́yìn, tí Ọlọ́run ti parun ní iwájú wọn. 26 Nítorí náà Ọlọ́run Israẹli ru ẹ̀mí Pulu ọba Asiria sókè (ẹ̀mí Tiglat-Pileseri ọba Asiria), ó si kó wọn lọ, àní àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase lọ sí ìgbèkùn. Ó sì kó wọn wá sí Hala, àti Habori, àti Harani, àti sí etí odò Gosani; títí dí òní yìí.

Now the sons of Reuben the firstborn of Israel, (for he was the firstborn; but forasmuch as he defiled his father's bed, his birthright was given unto the sons of Joseph the son of Israel: and the genealogy is not to be reckoned after the birthright.

For Judah prevailed above his brethren, and of him came the chief ruler; but the birthright was Joseph's:)

The sons, I say, of Reuben the firstborn of Israel were, Hanoch, and Pallu, Hezron, and Carmi.

The sons of Joel; Shemaiah his son, Gog his son, Shimei his son,

Micah his son, Reaia his son, Baal his son,

Beerah his son, whom Tilgathpilneser king of Assyria carried away captive: he was prince of the Reubenites.

And his brethren by their families, when the genealogy of their generations was reckoned, were the chief, Jeiel, and Zechariah,

And Bela the son of Azaz, the son of Shema, the son of Joel, who dwelt in Aroer, even unto Nebo and Baalmeon:

And eastward he inhabited unto the entering in of the wilderness from the river Euphrates: because their cattle were multiplied in the land of Gilead.

10 And in the days of Saul they made war with the Hagarites, who fell by their hand: and they dwelt in their tents throughout all the east land of Gilead.

11 And the children of Gad dwelt over against them, in the land of Bashan unto Salcah:

12 Joel the chief, and Shapham the next, and Jaanai, and Shaphat in Bashan.

13 And their brethren of the house of their fathers were, Michael, and Meshullam, and Sheba, and Jorai, and Jachan, and Zia, and Heber, seven.

14 These are the children of Abihail the son of Huri, the son of Jaroah, the son of Gilead, the son of Michael, the son of Jeshishai, the son of Jahdo, the son of Buz;

15 Ahi the son of Abdiel, the son of Guni, chief of the house of their fathers.

16 And they dwelt in Gilead in Bashan, and in her towns, and in all the suburbs of Sharon, upon their borders.

17 All these were reckoned by genealogies in the days of Jotham king of Judah, and in the days of Jeroboam king of Israel.

18 The sons of Reuben, and the Gadites, and half the tribe of Manasseh, of valiant men, men able to bear buckler and sword, and to shoot with bow, and skilful in war, were four and forty thousand seven hundred and threescore, that went out to the war.

19 And they made war with the Hagarites, with Jetur, and Nephish, and Nodab.

20 And they were helped against them, and the Hagarites were delivered into their hand, and all that were with them: for they cried to God in the battle, and he was intreated of them; because they put their trust in him.

21 And they took away their cattle; of their camels fifty thousand, and of sheep two hundred and fifty thousand, and of asses two thousand, and of men an hundred thousand.

22 For there fell down many slain, because the war was of God. And they dwelt in their steads until the captivity.

23 And the children of the half tribe of Manasseh dwelt in the land: they increased from Bashan unto Baalhermon and Senir, and unto mount Hermon.

24 And these were the heads of the house of their fathers, even Epher, and Ishi, and Eliel, and Azriel, and Jeremiah, and Hodaviah, and Jahdiel, mighty men of valour, famous men, and heads of the house of their fathers.

25 And they transgressed against the God of their fathers, and went a whoring after the gods of the people of the land, whom God destroyed before them.

26 And the God of Israel stirred up the spirit of Pul king of Assyria, and the spirit of Tilgathpilneser king of Assyria, and he carried them away, even the Reubenites, and the Gadites, and the half tribe of Manasseh, and brought them unto Halah, and Habor, and Hara, and to the river Gozan, unto this day.

Descendants of Reuben

The sons of Reuben the firstborn of Israel ((A)for he was the firstborn, but because (B)he defiled his father's couch, (C)his birthright was given to the sons of Joseph the son of Israel, so that he could not be enrolled as the oldest son; (D)though Judah became strong among his brothers and a (E)chief came from him, yet the birthright belonged to Joseph), the (F)sons of Reuben, the firstborn of Israel: Hanoch, Pallu, Hezron, and Carmi. The sons of Joel: Shemaiah his son, Gog his son, Shimei his son, Micah his son, Reaiah his son, Baal his son, Beerah his son, whom (G)Tiglath-pileser[a] king of Assyria carried away into exile; he was a chief of the Reubenites. And his kinsmen by their clans, (H)when the genealogy of their generations was recorded: the chief, Jeiel, and Zechariah, and Bela the son of Azaz, son of (I)Shema, son of Joel, who lived in (J)Aroer, as far as (K)Nebo and (L)Baal-meon. He also lived to the east as far as the entrance of the desert this side of the Euphrates, because their livestock had multiplied (M)in the land of Gilead. 10 And in the days of Saul they waged war against the (N)Hagrites, who fell into their hand. And they lived in their tents throughout all the region east of Gilead.

Descendants of Gad

11 The sons of Gad lived over against them in the land of Bashan as far as (O)Salecah: 12 Joel the chief, Shapham the second, Janai, and Shaphat in Bashan. 13 And their kinsmen according to their fathers' houses: Michael, Meshullam, Sheba, Jorai, Jacan, Zia and Eber, seven. 14 These were the sons of Abihail the son of Huri, son of Jaroah, son of Gilead, son of Michael, son of Jeshishai, son of Jahdo, son of Buz. 15 Ahi the son of Abdiel, son of Guni, was chief in their fathers' houses, 16 and they lived in Gilead, in Bashan and in its towns, and in all the pasturelands of (P)Sharon to their limits. 17 All of these were recorded in genealogies in the days of (Q)Jotham king of Judah, and in the days of (R)Jeroboam king of Israel.

18 The Reubenites, the Gadites, and the half-tribe of Manasseh had valiant men who carried shield and sword, and drew the bow, (S)expert in war, 44,760, able to go to war. 19 They waged war against the (T)Hagrites, (U)Jetur, Naphish, and Nodab. 20 And when they prevailed[b] over them, the Hagrites and all who were with them were given into their hands, (V)for they cried out to God in the battle, and he granted their urgent plea (W)because they trusted in him. 21 They carried off their livestock: 50,000 of their camels, 250,000 sheep, 2,000 donkeys, and 100,000 men alive. 22 For many fell, because the war was of God. And they lived (X)in their place until (Y)the exile.

The Half-Tribe of Manasseh

23 The members of the half-tribe of Manasseh lived in the land. They were very numerous from Bashan to Baal-hermon, (Z)Senir, and Mount Hermon. 24 These were the heads of their fathers' houses: Epher,[c] Ishi, Eliel, Azriel, Jeremiah, Hodaviah, and Jahdiel, mighty warriors, famous men, heads of their fathers' houses. 25 But they broke faith with the God of their fathers, and (AA)whored (AB)after the gods of the peoples of the land, whom God had destroyed before them. 26 So the God of Israel stirred up the spirit of (AC)Pul king of Assyria, the spirit of (AD)Tiglath-pileser king of Assyria, and he took them into exile, namely, the Reubenites, the Gadites, and the half-tribe of Manasseh, and brought them (AE)to Halah, (AF)Habor, Hara, and (AG)the river Gozan, to this day.

Footnotes

  1. 1 Chronicles 5:6 Hebrew Tilgath-pilneser; also verse 26
  2. 1 Chronicles 5:20 Or they were helped to prevail
  3. 1 Chronicles 5:24 Septuagint, Vulgate; Hebrew and Epher