1 Kọrinti 1:3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
3 (A)Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa àti Olúwa wa tí í ṣe Jesu Kristi.
Read full chapter
2 Kọrinti 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 (A)Oore-ọ̀fẹ́ sí yín àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Jesu Kristi Olúwa.
Read full chapter
Galatia 1:3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
3 (A)Oore-ọ̀fẹ́ sí yín àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wá àti Jesu Kristi Olúwa,
Read full chapter
Efesu 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Oore-ọ̀fẹ́ sí yín àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wá àti Jesu Kristi Olúwa.
Read full chapter
Filipi 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 (A)Oore-ọ̀fẹ́ sí yín, àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Olúwa wa Jesu Kristi.
Read full chapter
Kolose 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 (A)Sí àwọn ẹni mímọ́ àti àwọn arákùnrin àti arábìnrin nínú Kristi tí wọ́n ń gbé ní ìlú Kolose.
Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún un yín láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa.
Read full chapter
1 Tẹsalonika 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ọpẹ́ fún ìgbàgbọ́ àwọn ará Tẹsalonika
2 (A)Gbogbo ìgbà ni a máa ń fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run nítorí yín, a sì ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo pẹ̀lú.
Read full chapter
2 Tẹsalonika 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 (A)Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run baba àti Jesu Kristi Olúwa.
Read full chapter
1 Timotiu 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Sí Timotiu ọmọ mi nínú ìgbàgbọ́:
Oore-ọ̀fẹ́, àánú àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run baba àti Jesu Kristi Olúwa wa.
Read full chapter
2 Timotiu 1:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Sí Timotiu, ọmọ mi olùfẹ́ ọ̀wọ́n:
Oore-ọ̀fẹ́, àánú àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Kristi Jesu Olúwa wa.
Read full chapter
Titu 1:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
4 (A)Sí Titu, ọmọ mi tòótọ́ nínú ìgbàgbọ́ wa kan náà.
Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run baba àti Kristi Jesu Olùgbàlà wa.
Read full chapter
Filemoni 3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
3 (A)Oore-Ọ̀fẹ́ fún un yín àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa àti Jesu Kristi.
Read full chapter
2 Johanu 3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
3 Oore-ọ̀fẹ́, àánú, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, Ọmọ Baba, yóò wà pẹ̀lú wa nínú òtítọ́ àti nínú ìfẹ́.
Read full chapterCopyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.