Font Size
1 Timotiu 5:6
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
1 Timotiu 5:6
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
6 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá fi ara rẹ fún ayé jíjẹ, ó kú nígbà tí ó wà láààyè.
Read full chapter
Efesu 2:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Efesu 2:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣọdààyè nínú Kristi
2 Ní ti ẹ̀yin, ẹ̀yin ni ó sì ti sọ di ààyè, nígbà ti ẹ̀yin ti kú nítorí ìrékọjá àti àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín,
Read full chapter
Luku 9:60
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 9:60
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
60 Jesu sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí àwọn òkú máa sìnkú ara wọn: ṣùgbọ́n ìwọ lọ kí o sì máa wàásù ìjọba Ọlọ́run.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.