Add parallel Print Page Options

22 Nítorí orúkọ ńlá rẹ̀ Olúwa kì yóò kọ àwọn ènìyàn rẹ̀ sílẹ̀, nítorí tí inú Olúwa dùn láti fi yín ṣe ènìyàn rẹ̀.

Read full chapter

22 For the sake(A) of his great name(B) the Lord will not reject(C) his people, because the Lord was pleased to make(D) you his own.

Read full chapter

37 Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Àyàfi tí a bá lé àwọn ọ̀run lókè
    tí ìpìlẹ̀ ayé sì di àwárí ní ìsàlẹ̀,
ni èmi yóò kọ àwọn Israẹli
    nítorí ohun gbogbo tí wọ́n ti ṣe,”
    ni Olúwa wí.

Read full chapter

37 This is what the Lord says:

“Only if the heavens above can be measured(A)
    and the foundations of the earth below be searched out
will I reject(B) all the descendants of Israel
    because of all they have done,”
declares the Lord.

Read full chapter

24 “Ǹjẹ́ ìwọ kò kíyèsi pé àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń sọ pé: ‘Olúwa ti kọ àwọn ọba méjèèjì tí ó yàn sílẹ̀’? Nítorí náà, ni wọ́n ti ṣe kẹ́gàn àwọn ènìyàn mi. Wọn kò sì mọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè kan. 25 Báyìí ni Olúwa wí: ‘Bí èmi kò bá ti da májẹ̀mú mi pẹ̀lú ọ̀sán àti òru àti pẹ̀lú òfin ọ̀run àti ayé tí kò lè yẹ̀. 26 Nígbà náà ni èmi ó kọ ọmọlẹ́yìn Jakọbu àti Dafidi ìránṣẹ́ mi tí èmi kò sì ní yan ọ̀kan nínú ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ́ alákòóso lórí àwọn ọmọ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu; nítorí èmi ó mú ìkólọ wọn padà; èmi ó sì ṣàánú fún wọn.’ ”

Read full chapter

24 “Have you not noticed that these people are saying, ‘The Lord has rejected the two kingdoms[a](A) he chose’? So they despise(B) my people and no longer regard them as a nation.(C) 25 This is what the Lord says: ‘If I have not made my covenant with day and night(D) and established the laws(E) of heaven and earth,(F) 26 then I will reject(G) the descendants of Jacob(H) and David my servant and will not choose one of his sons to rule over the descendants of Abraham, Isaac and Jacob. For I will restore their fortunes[b](I) and have compassion(J) on them.’”

Read full chapter

Footnotes

  1. Jeremiah 33:24 Or families
  2. Jeremiah 33:26 Or will bring them back from captivity

22 Heberu ni wọ́n bí? Bẹ́ẹ̀ ni èmi. Israẹli ni wọ́n bí? Bẹ́ẹ̀ ni èmi. Irú-ọmọ Abrahamu ní òun bí? Bẹ́ẹ̀ ni èmi.

Read full chapter

22 Are they Hebrews? So am I.(A) Are they Israelites? So am I.(B) Are they Abraham’s descendants? So am I.(C)

Read full chapter

Ẹni tí a kọ nílà ní ọjọ́ kẹjọ, láti inú kùkùté Israẹli wá, láti inú ẹ̀yà Benjamini, Heberu láti inú Heberu wá; nítorí, ní ti òfin Farisi ni èmi;

Read full chapter

circumcised(A) on the eighth day, of the people of Israel,(B) of the tribe of Benjamin,(C) a Hebrew of Hebrews; in regard to the law, a Pharisee;(D)

Read full chapter