Add parallel Print Page Options

Ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tàn yín: ẹni tí ó bá ń ṣe òdodo, ó jásí olódodo, gẹ́gẹ́ bí òun tí jẹ olódodo. (A)Ẹni tí ó ba ń dẹ́ṣẹ̀ tí èṣù ni; nítorí láti àtètèkọ́ṣe ni èṣù ti ń dẹ́ṣẹ̀. Nítorí èyí ni ọmọ Ọlọ́run ṣe farahàn, kí ó lè pa iṣẹ́ èṣù run. (B)Ẹnikẹ́ni tí a ti ipa Ọlọ́run bí, kì í dẹ́ṣẹ̀; nítorí tí irú rẹ̀ ń gbé inú rẹ̀: kò sì lè dẹ́ṣẹ̀ nítorí pé a ti ti ipa Ọlọ́run bí i. 10 Nínú èyí ni àwọn ọmọ Ọlọ́run ń farahàn, àti àwọn ọmọ èṣù; ẹnikẹ́ni tí kò ba ń ṣe òdodo, àti ẹni tí kò fẹ́ràn arákùnrin rẹ̀ kì í ṣe ti Ọlọ́run.

Read full chapter

Dear children,(A) do not let anyone lead you astray.(B) The one who does what is right is righteous, just as he is righteous.(C) The one who does what is sinful is of the devil,(D) because the devil has been sinning from the beginning. The reason the Son of God(E) appeared was to destroy the devil’s work.(F) No one who is born of God(G) will continue to sin,(H) because God’s seed(I) remains in them; they cannot go on sinning, because they have been born of God. 10 This is how we know who the children of God(J) are and who the children of the devil(K) are: Anyone who does not do what is right is not God’s child, nor is anyone who does not love(L) their brother and sister.(M)

Read full chapter

Ìfẹ́ Ọlọ́run àti ti àwa

(A)Olùfẹ́, ẹ jẹ́ kí a fẹ́ràn ara wa: nítorí ìfẹ́ ti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá; àti gbogbo ẹni tí ó bá ní ìfẹ́, a bí i nípa ti Ọlọ́run, ó sì mọ Ọlọ́run.

Read full chapter

God’s Love and Ours

Dear friends, let us love one another,(A) for love comes from God. Everyone who loves has been born of God(B) and knows God.(C)

Read full chapter