耶和華譴責以色列

以色列人啊,
你們要聽耶和華的話:
「起來,你們要在高山面前申辯,
讓丘陵聽你們訴說。
群山啊,大地永固的根基啊,
你們要聽耶和華的控告!
因為耶和華要控告祂的子民,
責備以色列人。

「我的子民啊,
我做了什麼對不起你們的事?
我哪裡令你們厭煩?
回答我!
我曾帶領你們離開埃及,
把你們從受奴役之地救贖出來,
又差遣摩西、亞倫和米利暗引領你們。
我的子民啊,
你們要回想摩押王巴勒的陰謀以及比珥之子巴蘭給他的回答,
要回想你們從什亭到吉甲途中的遭遇,
以便認識耶和華公義的作為。」

我要拿什麼朝見耶和華,
在天上的上帝面前叩拜呢?
要獻上一歲的牛犢作燔祭嗎?
耶和華會喜愛成千的公羊和萬條油河嗎?
我要因過犯而獻上自己的長子,
因心中的罪惡而獻上親生的骨肉嗎?
世人啊,
耶和華已經指示你們何為良善。
祂向你們所要的是什麼呢?
是要你們行公義,好憐憫,
謙卑地與你們的上帝同行。

耶和華在向耶路撒冷呼喊,
智者必敬畏祂的名。祂說:
「聚在城裡的眾人啊,你們要聽!
10 我豈會忘記惡人家中的不義之財和可惡的小升斗?
11 我豈會放過使用不公道的秤和法碼的人?
12 城中的富人殘暴成性,
居民謊話連篇,
滿口詭詐之言。
13 所以,我要重重地擊打你,
因你的罪惡而毀滅你。
14 你吃,卻吃不飽,仍然腹中空空。
你聚斂錢財,卻保不住。
你保住的,我要交給拿刀的。
15 你撒種,卻不得收割;
你榨橄欖,卻無油抹身;
你踩葡萄,卻無酒可喝。
16 因為你遵守暗利的惡規,
效法亞哈家的惡行,
隨從他們的計謀,
所以我要使你荒涼,
讓你的居民成為笑柄。
你們要蒙受列國的羞辱。」

Ọlọ́run pe Israẹli níjà

Ẹ fi etí sí ohun tí Olúwa wí:

“Dìde dúró, bẹ ẹ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ rẹ níwájú òkè ńlá;
    sì jẹ́ kí àwọn òkè kéékèèkéé gbọ́ ohun tí ó fẹ́ wí.

“Gbọ́, ìwọ òkè ńlá, ẹ̀sùn Olúwa;
    gbọ́, ìwọ ìpìlẹ̀ ilé ayérayé.
Nítorí Olúwa ń bá àwọn ènìyàn rẹ̀ wíjọ́;
    òun yóò sì bá Israẹli rojọ́.

“Ẹ̀yin ènìyàn mi, kí ni mo ṣe fún yín?
    Àti nínú kí ni mo ti dá yin lágara? Dá mi lóhùn.
Nítorí èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá,
    mo sì rà yín padà láti ilẹ̀ ẹrú wá.
Mo rán Mose láti darí yín,
    bákan náà mo rán Aaroni àti Miriamu síwájú rẹ̀.
Ìwọ ènìyàn mi,
    rántí ohun tí Balaki ọba Moabu gbèrò
    àti ohun tí Balaamu ọmọ Beori dáhùn.
Rántí ìrìnàjò rẹ̀ láti Ṣittimu dé Gilgali,
    kí ìwọ ba le mọ òdodo Olúwa.”

Kí ni èmi yóò ha mú wá síwájú Olúwa
    tí èmi ó fi tẹ ara mi ba níwájú Ọlọ́run gíga?
Kí èmi ha wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun,
    pẹ̀lú ọmọ màlúù ọlọ́dún kan?
Ǹjẹ́ Olúwa yóò ní inú dídùn sí ẹgbẹgbàarùn-ún àgbò,
    tàbí sí ẹgbẹgbàarùn-ún ìṣàn òróró?
Èmi yóò ha fi àkọ́bí mi sílẹ̀ fún ìré-òfin-kọjá mi,
    èso inú ara mi fún ẹ̀ṣẹ̀ ọkàn mi?
Ó ti fihàn ọ́, ìwọ ènìyàn, ohun tí ó dára,
    àti ohun tí Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ?
Bí kò ṣe láti ṣe òtítọ́, kí o sì fẹ́ràn àánú,
    àti kí o rìn ní ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run rẹ̀.

Ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli àti ìjìyà wọn

Gbọ́! Ohùn Olúwa kígbe sí ìlú ńlá náà,
    láti jẹ ọlọ́gbọ́n ni láti bẹ̀rù orúkọ rẹ.
    “Ẹ kíyèsi ọ̀pá rẹ̀ gbọ́ ọ̀pá àti Ẹni náà tí ó yàn án
10 Ǹjẹ́ ìṣúra ìwà búburú ha wà
    ní ilé ènìyàn búburú síbẹ̀,
    àti òṣùwọ̀n àìkún tí ó jẹ́ ohun ìbínú?
11 Ǹjẹ́ èmi ha lè kà wọ́n sí mímọ́
    pẹ̀lú òṣùwọ̀n búburú,
    pẹ̀lú àpò òṣùwọ̀n ẹ̀tàn?
12 Àwọn ọlọ́rọ̀ inú rẹ̀ kún fún ìwà ipá;
    àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ ti ọ̀rọ̀ èké
    àti ahọ́n wọn ń sọ ẹ̀tàn?
13 Nítorí náà ni èmi yóò ṣe mú ọ ṣàìsàn ní lílù ọ́,
    láti sọ ọ́ dahoro nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ.
14 Ìwọ yóò jẹun ṣùgbọ́n kì yóò yó;
    ìyàn yóò wà láàrín rẹ;
Ìwọ yóò kó pamọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò lò láìléwu,
    nítorí ohun tí ìwọ kò pamọ́ ni èmi yóò fi fún idà.
15 Ìwọ yóò gbìn ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò kórè
    ìwọ yóò tẹ olifi,
ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò fi òróró rẹ̀ kún ara rẹ;
    ìwọ yóò tẹ èso àjàrà, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò mu wáìnì.
16 Nítorí tí ìwọ ti pa òfin Omri mọ́,
    àti gbogbo iṣẹ́ ilé Ahabu,
    tí ó sì ti tẹ̀lé ìmọ̀ràn wọn,
nítorí náà ni èmi yóò ṣe mú ọ fún ìparun
    àti àwọn ènìyàn rẹ fún ìfiṣe ẹlẹ́yà;
    ìwọ yóò sì ru ẹ̀gàn àwọn ènìyàn mi.”

God Pleads with Israel

Hear now what the Lord says:

“Arise, plead your case before the mountains,
And let the hills hear your voice.
(A)Hear, O you mountains, (B)the Lord’s complaint,
And you strong foundations of the earth;
For (C)the Lord has a complaint against His people,
And He will [a]contend with Israel.

“O My people, what (D)have I done to you?
And how have I (E)wearied you?
Testify against Me.
(F)For I brought you up from the land of Egypt,
I redeemed you from the house of bondage;
And I sent before you Moses, Aaron, and Miriam.
O My people, remember now
What (G)Balak king of Moab counseled,
And what Balaam the son of Beor answered him,
From [b]Acacia Grove to Gilgal,
That you may know (H)the righteousness of the Lord.”

With what shall I come before the Lord,
And bow myself before the High God?
Shall I come before Him with burnt offerings,
With calves a year old?
(I)Will the Lord be pleased with thousands of rams,
Ten thousand (J)rivers of oil?
(K)Shall I give my firstborn for my transgression,
[c]The fruit of my body for the sin of my soul?

He has (L)shown you, O man, what is good;
And what does the Lord require of you
But (M)to do justly,
To love [d]mercy,
And to walk humbly with your God?

Punishment of Israel’s Injustice

The Lord’s voice cries to the city—
Wisdom shall see Your name:

“Hear the rod!
Who has appointed it?
10 Are there yet the treasures of wickedness
In the house of the wicked,
And the short measure that is an abomination?
11 Shall I count pure those with (N)the wicked scales,
And with the bag of deceitful weights?
12 For her rich men are full of (O)violence,
Her inhabitants have spoken lies,
And (P)their tongue is deceitful in their mouth.

13 “Therefore I will also (Q)make you sick by striking you,
By making you desolate because of your sins.
14 (R)You shall eat, but not be satisfied;
[e]Hunger shall be in your midst.
You may carry some away,[f] but shall not save them;
And what you do rescue I will give over to the sword.

15 “You shall (S)sow, but not reap;
You shall tread the olives, but not anoint yourselves with oil;
And make sweet wine, but not drink wine.
16 For the statutes of (T)Omri are (U)kept;
All the works of Ahab’s house are done;
And you walk in their counsels,
That I may make you a [g]desolation,
And your inhabitants a hissing.
Therefore you shall bear the (V)reproach of [h]My people.”

Footnotes

  1. Micah 6:2 bring charges against
  2. Micah 6:5 Heb. Shittim, Num. 25:1; Josh. 2:1; 3:1
  3. Micah 6:7 My own child
  4. Micah 6:8 Or lovingkindness
  5. Micah 6:14 Or Emptiness or Humiliation
  6. Micah 6:14 Tg., Vg. You shall take hold
  7. Micah 6:16 Or object of horror
  8. Micah 6:16 So with MT, Tg., Vg.; LXX nations