Add parallel Print Page Options

Timotiu darapọ̀ mọ́ Paulu àti Sila

16 Ó sì wá sí Dabe àti Lysra: sí kíyèsi i, ọmọ-ẹ̀yìn kan wà níbẹ̀, tí a ń pè ní Timotiu, ọmọ obìnrin kan tí í ṣe Júù, tí ó gbàgbọ́; ṣùgbọ́n Giriki ní baba rẹ̀. Ẹni tí a ròhìn rẹ̀ ní rere lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin tí ó wà ní Lysra àti Ikoniomu. Òun ni Paulu fẹ́ kí ó bá òun lọ; ó sì mú un, ó sì kọ ọ́ ní ilà, nítorí àwọn Júù tí ó wà ní agbègbè wọ̀nyí: nítorí gbogbo wọn mọ̀ pé, Giriki ni baba rẹ̀. Bí wọn sì ti ń la àwọn ìlú lọ, wọ́n ń fi àwọn àṣẹ, tí a tí pinnu láti ọ̀dọ̀ àwọn aposteli àti àwọn alàgbà tí ó wà ní Jerusalẹmu, lé wọn lọ́wọ́ láti máa pa wọ́n mọ́. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìjọ sì fẹsẹ̀múlẹ̀ ní ìgbàgbọ́, wọn sí ń pọ̀ sí i ní iye lójoojúmọ́.

Ìran Paulu nípa arákùnrin Makedonia

Wọ́n sì la agbègbè Frigia já, àti Galatia, nítorí tí Ẹ̀mí Mímọ́ kọ̀ fún wọn láti sọ ọ̀rọ̀ náà ni Asia. Nígbà tí wọ́n dé ọ̀kánkán Misia, wọ́n gbìyànjú láti lọ sí Bitinia, ṣùgbọ́n Ẹ̀mí Jesu kò gbà fún wọn. Nígbà tí wọ́n sì kọjá lẹ́bàá Misia, wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ sí Troasi. Ìran kan si hàn sì Paulu ni òru: Ọkùnrin kan ará Makedonia dúró, ó sì ń bẹ̀ ẹ́, wí pé, “Rékọjá wá sí Makedonia, kí o sí ràn wá lọ́wọ́!” 10 Nígbà tí ó sì tí rí ìran náà, lọ́gán ó múra láti lọ sí Makedonia, a ka á sí pé, Ọlọ́run tí pè wá láti wàásù ìhìnrere fún wọn.

Ìyípadà Lidia ní Filipi

11 Nítorí náà nígbà tí àwa ṣíkọ̀ ní Troasi a ba ọ̀nà tààrà lọ sí Samotrakea, ni ọjọ́ kejì a sì dé Neapoli; 12 Láti ibẹ̀ àwa sì lọ si Filipi, tí í ṣe ìlú Makedonia, olú ìlú ìhà ibẹ̀, ìlú lábẹ́ Romu, àwa sì jókòó ní ìlú yìí fún ọjọ́ mélòókan.

13 Lọ́jọ́ ìsinmi, àwa sí jáde lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú náà, lẹ́bàá odò kan, níbi tí a rò pé ibi àdúrà wà; àwa sí jókòó, a sì bá àwọn obìnrin tí o péjọ sọ̀rọ̀. 14 Àti obìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Lidia, elése àlùkò, ará ìlú Tiatira, ẹni tí ó sin Ọlọ́run, ó gbọ́ ọ̀rọ̀ wa, ọkàn ẹni tí Olúwa ṣí láti fetísí ohun tí a tí ẹnu Paulu sọ. 15 Nígbà tí a sí bamitiisi rẹ̀, àti àwọn ara ilé rẹ̀, ó bẹ̀ wá, wí pé, “Bí ẹ̀yin bá kà mí ni olóòtítọ́ sí Olúwa, ẹ wá si ilé mi, kí ẹ sí wọ̀ níbẹ̀!” O sí rọ̀ wá.

Paulu àti Sila nínú túbú

16 Bí àwa tí n lọ sí ibi àdúrà náà, ọmọbìnrin kan tí o ní ẹ̀mí àfọ̀ṣẹ, pàdé wa, ẹni tí ó fi àfọ̀ṣẹ mú èrè púpọ̀ wá fún àwọn ọ̀gá rẹ̀: 17 Òun náà ni ó ń tọ Paulu àti àwa lẹ́hìn, ó sì ń kígbe, pé, “Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ni ìránṣẹ́ Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo, tí ń kéde ọ̀nà ìgbàlà fún yin!” 18 Ó sì ń ṣe èyí lọ́jọ́ púpọ̀, ṣùgbọ́n nígbà tí inú Paulu bàjẹ́, tí ó sì yípadà, ó wí fún ẹ̀mí náà pé, “Mo pàṣẹ fún ọ ní orúkọ Jesu Kristi kí o jáde kúrò lára rẹ̀!” Ó sí jáde ni wákàtí kan náà.

19 Nígbà tí àwọn ọ̀gá rẹ̀ sì rí i pé, ìgbẹ́kẹ̀lé èrè wọn pin, wọ́n mú Paulu àti Sila, wọn sì wọ́ wọn lọ sí ọjà tọ àwọn aláṣẹ lọ; 20 Nígbà tí wọ́n sì mú wọn tọ àwọn onídàájọ́ lọ, wọ́n wí pé, “Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí tí í ṣe Júù, wọ́n ń yọ ìlú wa lẹ́nu jọjọ; 21 Wọ́n sì ń kọ́ni ní àṣà tí kò yẹ fún wa, àwa ẹni tí í ṣe ara Romu, láti gbà àti láti tẹ̀lé.”

22 (A)Ọ̀pọ̀ ènìyàn sí jùmọ̀ dìde sì Paulu àti Sila. Àwọn olórí sí fà wọ́n ní aṣọ ya, wọ́n sí pàṣẹ pé, ki a fi ọ̀gọ̀ lù wọ́n. 23 Nígbà tí wọ́n sì lù wọ́n púpọ̀, wọ́n sọ wọ́n sínú túbú, wọ́n kìlọ̀ fún onítúbú kí ó pa wọ́n mọ́ dáradára: 24 Nígbà tí ó gbọ́ irú ìkìlọ̀ bẹ́ẹ̀, ó sọ̀ wọ́n sínú túbú tí inú lọ́hùn, ó sí kan àbà mọ wọ́n lẹ́sẹ̀.

25 Ṣùgbọ́n láàrín ọ̀gànjọ́ Paulu àti Sila ń gbàdúrà, wọ́n sì ń kọrin ìyìn si Ọlọ́run: àwọn ara túbú sì ń tẹ́tí sí wọn. 26 Lójijì ilẹ̀ mímì ńlá sì mi, tó bẹ́ẹ̀ tí ìpìlẹ̀ ilé túbú mì tìtì: lọ́gán, gbogbo ìlẹ̀kùn sì ṣí, ìdè gbogbo wọn sì tú sílẹ̀. 27 Nígbà tí onítúbú si tají, tí o sì ri pé, àwọn ìlẹ̀kùn túbú tí ṣí sílẹ̀, ó fa idà rẹ̀ yọ, ó sì fẹ́ pa ara rẹ̀, ó ṣe bí àwọn ara túbú ti sálọ. 28 Ṣùgbọ́n Paulu gbé ohun rẹ̀ sókè, wí pé, “Má ṣe pa ara rẹ lára: nítorí gbogbo wa ń bẹ níhìn-ín yìí!”

29 Nígbà tí ó sì béèrè iná, ó bẹ́ wọ inú ilé, ó ń wárìrì, ó wólẹ̀ níwájú Paulu àti Sila. 30 Ó sì mú wọn jáde, ó ní, “Alàgbà, kín ni ki èmi ṣe ki n lè là?”

31 Wọ́n sì wí fún un pé, “Gbá Jesu Kristi Olúwa gbọ́, a ó sì gbà ọ́ là, ìwọ àti àwọn ará ilé rẹ pẹ̀lú.” 32 Wọ́n sì sọ ọ̀rọ̀ Olúwa fún un, àti fún gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀. 33 Ó sì mú wọn ní wákàtí náà lóru, ó wẹ ọgbẹ́ wọn; a sì bamitiisi rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ lójúkan náà. 34 Ó sì mú wọn wá sí ilé rẹ̀, ó sì gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú wọn, ó sì yọ̀ gidigidi pẹ̀lú gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, nítorí ó gba Ọlọ́run gbọ́.

35 Ṣùgbọ́n nígbà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn onídàájọ́ rán àwọn ọlọ́pàá pé, “Tú àwọn ènìyàn náà sílẹ̀.” 36 Onítúbú sì sọ ọ̀rọ̀ náà fún Paulu, wí pé, “Àwọn onídàájọ́ ránṣẹ́ pé kí á da ìwọ àti Sila sílẹ̀. Ǹjẹ́ nísinsin yìí ẹ jáde kí ẹ sì máa lọ ní àlàáfíà.”

37 Ṣùgbọ́n Paulu wí fún wọn pé, “Wọ́n lù wá ni gbangba, wọ́n sì sọ wá sínú túbú ni àìjẹ̀bi, àwa ẹni tí ì ṣe ara Romu. Ṣe nísinsin yìí wọ́n fẹ́ tì wá jáde níkọ̀kọ̀? Rara! Ṣùgbọ́n kí àwọn tìkára wọn wá mú wa jáde!”

38 Àwọn ọlọ́pàá sì sọ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn onídàájọ́: ẹ̀rù sì bà wọ́n, nígbà tí wọ́n gbọ́ pé ará Romu ni Paulu àti Sila. 39 Wọ́n sì wá, wọ́n ṣìpẹ̀ lọ́dọ̀ wọ́n, wọn sì mú wọn jáde, wọ́n sì bẹ̀ wọ́n pé, ki wọn jáde kúrò ni ìlú náà. 40 Paulu àti Sila sì jáde nínú túbú, wọ́n sì wọ ilé Lidia lọ: nígbà tí wọn sì tí rí àwọn arákùnrin, wọ́n tù wọ́n nínú, wọn sì jáde kúrò.

Timothy Joins Paul and Silas

16 Paul[a] came also to Derbe and to Lystra. A disciple was there, named (A)Timothy, (B)the son of a Jewish woman who was a believer, but his father was a Greek. He was well spoken of by (C)the brothers[b] at Lystra and Iconium. Paul wanted Timothy to accompany him, and he (D)took him and circumcised him because of the Jews who were in those places, for they all knew that his father was a Greek. As they went on their way through the cities, they delivered to them for observance (E)the decisions (F)that had been reached by (G)the apostles and elders who were in Jerusalem. (H)So the churches were strengthened in (I)the faith, and they increased in numbers (J)daily.

The Macedonian Call

And (K)they went through the region of Phrygia and Galatia, having been forbidden by the Holy Spirit to speak the word in Asia. And when they had come up to Mysia, they attempted to go into Bithynia, but (L)the Spirit of Jesus did not allow them. So, passing by Mysia, they went down (M)to Troas. And a vision appeared to Paul in the night: a man of Macedonia was standing there, urging him and saying, “Come over to Macedonia and help us.” 10 And when Paul[c] had seen the vision, immediately (N)we sought to go on into Macedonia, concluding that God had called us to preach the gospel to them.

The Conversion of Lydia

11 So, setting sail from Troas, we (O)made a direct voyage to Samothrace, and the following day to Neapolis, 12 and from there to (P)Philippi, which is a leading city of the[d] district of Macedonia and (Q)a Roman colony. We remained in this city some days. 13 And (R)on the Sabbath day we went outside the gate (S)to the riverside, where we supposed there was a place of prayer, and we (T)sat down and spoke to the women who had come together. 14 One who heard us was a woman named Lydia, from the city of Thyatira, a seller of purple goods, (U)who was a worshiper of God. The Lord (V)opened her heart to pay attention to what was said by Paul. 15 And after she was baptized, (W)and her household as well, she urged us, saying, “If you have judged me to be faithful to the Lord, come to my house and stay.” And she (X)prevailed upon us.

Paul and Silas in Prison

16 As we were going to (Y)the place of prayer, we were met by a slave girl who had (Z)a spirit of (AA)divination and (AB)brought her owners much gain by fortune-telling. 17 She followed Paul and us, (AC)crying out, “These men are (AD)servants of (AE)the Most High God, who proclaim to you (AF)the way of salvation.” 18 And this she kept doing for many days. Paul, having become greatly annoyed, turned and said to the spirit, (AG)“I command you (AH)in the name of Jesus Christ to come out of her.” And (AI)it came out that very hour.

19 But (AJ)when her owners saw that their hope of gain was gone, they seized Paul and Silas and (AK)dragged them into the marketplace before the rulers. 20 And when they had brought them to the magistrates, they said, “These men are Jews, and they are disturbing our city. 21 They (AL)advocate customs that are not lawful for us (AM)as Romans to accept or practice.” 22 The crowd joined in attacking them, and the magistrates tore the garments off them and gave orders (AN)to beat them with rods. 23 And when they had inflicted many blows upon them, they threw them into prison, ordering the jailer to keep them safely. 24 Having received this order, he put them into the inner (AO)prison and fastened their feet in (AP)the stocks.

The Philippian Jailer Converted

25 (AQ)About midnight Paul and Silas were praying and singing hymns to God, and the prisoners were listening to them, 26 and suddenly (AR)there was a great earthquake, so that the foundations of the prison were shaken. And immediately (AS)all the doors were opened, and (AT)everyone's bonds were unfastened. 27 When the jailer woke and saw that the prison doors were open, he drew his sword and (AU)was about to kill himself, supposing that the prisoners had escaped. 28 But Paul cried with a loud voice, “Do not harm yourself, for we are all here.” 29 And the jailer[e] called for lights and rushed in, and trembling with fear he (AV)fell down before Paul and Silas. 30 Then he brought them out and said, “Sirs, (AW)what must I do to be (AX)saved?” 31 And they said, (AY)“Believe in the Lord Jesus, and you will be saved, you (AZ)and your household.” 32 And they spoke the word of the Lord to him and to all who were in his house. 33 And he took them (BA)the same hour of the night and washed their wounds; and he (BB)was baptized at once, he and all his family. 34 Then he brought them up into his house and set food before them. And he (BC)rejoiced along with his entire household that he had believed in God.

35 But when it was day, the magistrates sent the police, saying, “Let those men go.” 36 And the jailer reported these words to Paul, saying, “The magistrates have sent to let you go. Therefore come out now and go in peace.” 37 But Paul said to them, “They have beaten us publicly, (BD)uncondemned, men who are Roman citizens, and have thrown us into prison; and do they now throw us out secretly? No! Let them come themselves and take us out.” 38 The police reported these words to the magistrates, and (BE)they were afraid when they heard that they were Roman citizens. 39 So they came and apologized to them. And they took them out and (BF)asked them to leave the city. 40 So they went out of the prison and visited (BG)Lydia. And when they had seen (BH)the brothers, they encouraged them and departed.

Footnotes

  1. Acts 16:1 Greek He
  2. Acts 16:2 Or brothers and sisters; also verse 40
  3. Acts 16:10 Greek he
  4. Acts 16:12 Or that
  5. Acts 16:29 Greek he

Timothy Joins Paul and Silas

16 Then he came to (A)Derbe and Lystra. And behold, a certain disciple was there, (B)named Timothy, (C)the son of a certain Jewish woman who believed, but his father was Greek. He was well spoken of by the brethren who were at Lystra and Iconium. Paul wanted to have him go on with him. And he (D)took him and circumcised him because of the Jews who were in that region, for they all knew that his father was Greek. And as they went through the cities, they delivered to them the (E)decrees to keep, (F)which were determined by the apostles and elders at Jerusalem. (G)So the churches were strengthened in the faith, and increased in number daily.

The Macedonian Call

Now when they had gone through Phrygia and the region of (H)Galatia, they were forbidden by the Holy Spirit to preach the word in [a]Asia. After they had come to Mysia, they tried to go into Bithynia, but the [b]Spirit did not permit them. So passing by Mysia, they (I)came down to Troas. And a vision appeared to Paul in the night. A (J)man of Macedonia stood and pleaded with him, saying, “Come over to Macedonia and help us.” 10 Now after he had seen the vision, immediately we sought to go (K)to Macedonia, concluding that the Lord had called us to preach the gospel to them.

Lydia Baptized at Philippi

11 Therefore, sailing from Troas, we ran a straight course to Samothrace, and the next day came to Neapolis, 12 and from there to (L)Philippi, which is the [c]foremost city of that part of Macedonia, a colony. And we were staying in that city for some days. 13 And on the Sabbath day we went out of the city to the riverside, where prayer was customarily made; and we sat down and spoke to the women who met there. 14 Now a certain woman named Lydia heard us. She was a seller of purple from the city of (M)Thyatira, who worshiped God. (N)The Lord opened her heart to heed the things spoken by Paul. 15 And when she and her household were baptized, she begged us, saying, “If you have judged me to be faithful to the Lord, come to my house and stay.” So (O)she persuaded us.

Paul and Silas Imprisoned

16 Now it happened, as we went to prayer, that a certain slave girl (P)possessed with a spirit of divination met us, who brought her masters (Q)much profit by fortune-telling. 17 This girl followed Paul and us, and cried out, saying, “These men are the servants of the Most High God, who proclaim to us the way of salvation.” 18 And this she did for many days.

But Paul, (R)greatly [d]annoyed, turned and said to the spirit, “I command you in the name of Jesus Christ to come out of her.” (S)And he came out that very hour. 19 But (T)when her masters saw that their hope of profit was gone, they seized Paul and Silas and (U)dragged them into the marketplace to the authorities.

20 And they brought them to the magistrates, and said, “These men, being Jews, (V)exceedingly trouble our city; 21 and they teach customs which are not lawful for us, being Romans, to receive or observe.” 22 Then the multitude rose up together against them; and the magistrates tore off their clothes (W)and commanded them to be beaten with rods. 23 And when they had laid many stripes on them, they threw them into prison, commanding the jailer to keep them securely. 24 Having received such a charge, he put them into the inner prison and fastened their feet in the stocks.

The Philippian Jailer Saved

25 But at midnight Paul and Silas were praying and singing hymns to God, and the prisoners were listening to them. 26 (X)Suddenly there was a great earthquake, so that the foundations of the prison were shaken; and immediately (Y)all the doors were opened and everyone’s chains were loosed. 27 And the keeper of the prison, awaking from sleep and seeing the prison doors open, supposing the prisoners had fled, drew his sword and was about to kill himself. 28 But Paul called with a loud voice, saying, “Do yourself no harm, for we are all here.”

29 Then he called for a light, ran in, and fell down trembling before Paul and Silas. 30 And he brought them out and said, (Z)“Sirs, what must I do to be saved?”

31 So they said, (AA)“Believe on the Lord Jesus Christ, and you will be saved, you and your household.” 32 Then they spoke the word of the Lord to him and to all who were in his house. 33 And he took them the same hour of the night and washed their stripes. And immediately he and all his family were baptized. 34 Now when he had brought them into his house, (AB)he set food before them; and he rejoiced, having believed in God with all his household.

Paul Refuses to Depart Secretly

35 And when it was day, the magistrates sent the [e]officers, saying, “Let those men go.”

36 So the keeper of the prison reported these words to Paul, saying, “The magistrates have sent to let you go. Now therefore depart, and go in peace.”

37 But Paul said to them, “They have beaten us openly, uncondemned (AC)Romans, and have thrown us into prison. And now do they put us out secretly? No indeed! Let them come themselves and get us out.”

38 And the officers told these words to the magistrates, and they were afraid when they heard that they were Romans. 39 Then they came and pleaded with them and brought them out, and (AD)asked them to depart from the city. 40 So they went out of the prison (AE)and entered the house of Lydia; and when they had seen the brethren, they encouraged them and departed.

Footnotes

  1. Acts 16:6 The Roman province of Asia
  2. Acts 16:7 NU adds of Jesus
  3. Acts 16:12 Lit. first
  4. Acts 16:18 distressed
  5. Acts 16:35 lictors, lit. rod bearers