Add parallel Print Page Options

11 Nígbà tí ojú Peteru sì wálẹ̀, ó ní, “Nígbà yìí ni mo tó mọ̀ nítòótọ́ pé, Olúwa rán angẹli rẹ̀, ó sì gbà mi lọ́wọ́ Herodu àti gbogbo ohun tí àwọn ènìyàn Júù ń retí!”

Read full chapter

11 Then Peter came to himself(A) and said, “Now I know without a doubt that the Lord has sent his angel and rescued me(B) from Herod’s clutches and from everything the Jewish people were hoping would happen.”

Read full chapter