Add parallel Print Page Options

Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin.

87 Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni
    ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.

Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀,
    ìlú Ọlọ́run;
“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli
    láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi:
Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi
    yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’ ”
Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ,
    “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀,
    àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀:
    “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”

Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu
    ohun èlò orin yóò wí pé,
    “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”

87 1-3 He founded Zion on the Holy Mountain—
    and oh, how God loves his home!
Loves it far better than all
    the homes of Jacob put together!
God’s hometown—oh!
    everyone there is talking about you!

I name them off, those among whom I’m famous:
    Egypt and Babylon,
    also Philistia,
    even Tyre, along with Cush.
Word’s getting around; they point them out:
    “This one was born again here!”

The word’s getting out on Zion:
    “Men and women, right and left,
    get born again in her!”

God registers their names in his book:
    “This one, this one, and this one—
    born again, right here.”

Singers and dancers give credit to Zion:
    “All my springs are in you!”