Add parallel Print Page Options

Lẹ́yìn ìgbà tí ó gba ọmú lẹ́nu Lo-rúhámà, ó sì lóyún ó sì bí ọmọkùnrin mìíràn. Nígbà náà ni Olúwa sì sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-Ammi, nítorí pé ẹ kì í ṣe ènìyàn mi, èmi náà kì í sì í ṣe Ọlọ́run yín.

10 “Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli yóò pọ̀ bí i iyanrìn etí Òkun tí a kò le wọ́n, tí a kò sì le è kà, yóò sì ṣe. Ní ibi tí wọ́n ti sọ fún wọn pé. ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó ti máa pè wọ́n ní ‘ọmọ Ọlọ́run alààyè.’

Read full chapter

А като отби Ло-рухама, зачна и роди син.

И <Господ> рече: Наречи го Ло-аммий {Т.е., Не люде мои.}; защото вие не сте Мои люде и Аз не ще бъда ваш <Бог>.

10 Но все пак числото на израилтяните ще бъде като морския пясък, който не може да се претегли нито да се изброи; и вместо онова, което им се каза, че: Не сте Мои люде, ще им се рече: Вий сте чада на живия Бог.

Read full chapter