Add parallel Print Page Options

wọ́n sì sọ̀rọ̀ lòdì sí Ọlọ́run àti Mose, wọ́n wí pé, “Èéṣe tí ìwọ fi mú wa jáde láti Ejibiti kí a ba le wá kú sí aginjù yìí? Kò sí oúnjẹ! Kò sì sí omi! Àwa sì kórìíra oúnjẹ tí kò dára yìí!”

Nígbà náà ni Olúwa rán ejò olóró sí àárín wọn; wọ́n gé àwọn ènìyàn jẹ, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Israẹli sì kú.

Read full chapter

they spoke against God(A) and against Moses, and said, “Why have you brought us up out of Egypt(B) to die in the wilderness?(C) There is no bread! There is no water!(D) And we detest this miserable food!”(E)

Then the Lord sent venomous snakes(F) among them; they bit the people and many Israelites died.(G)

Read full chapter