Add parallel Print Page Options

22 (A)Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn òbí rẹ̀ sọ, nítorí tí wọ́n bẹ̀rù àwọn Júù: nítorí àwọn Júù ti fohùn ṣọ̀kan pé bí ẹnìkan bá jẹ́wọ́ pé Kristi ni, wọn ó yọ ọ́ kúrò nínú Sinagọgu.

Read full chapter

22 His parents said this because they were afraid of the Jewish leaders,(A) who already had decided that anyone who acknowledged that Jesus was the Messiah would be put out(B) of the synagogue.(C)

Read full chapter

22 (A)Alábùkún fún ni ẹ̀yin, nígbà tí àwọn ènìyàn bá kórìíra yín,
    tí wọ́n bá yà yín kúrò nínú ẹgbẹ́ wọn, tí wọ́n bá gàn yín,
    tí wọ́n bá ta orúkọ yín nù bí ohun búburú,
        nítorí ọmọ ènìyàn.

Read full chapter

22 Blessed are you when people hate you,
    when they exclude you(A) and insult you(B)
    and reject your name as evil,
        because of the Son of Man.(C)

Read full chapter